3rd Lagos State House of Assembly
Ìrísí
3rd Lagos State House of Assembly | |
|---|---|
| Lagos State House of Assembly | |
| Type | |
| Type | |
Term limits | 4 years |
| History | |
| Founded | October 2, 1979 |
| Leadership | |
Rt. Hon. Shakirudeen Kinyomi since January 14, 1992 | |
Deputy Speaker | Rasheed Adebolale Fashina since January 14, 1992 |
Leader of the House | Adebayo T. Higara since January 14, 1992 |
Deputy Leader | Hon. Babatunde Oduala since January 14, 1992 |
Chief Whip | S. O Solaja |
| Structure | |
| Seats | 41 |
Length of term | 4 years |
| Elections | |
| Direct election | |
Last election | June 1, 1999 |
| Website | |
| The 3rd Lagos State House of Assembly | |

Ile-igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko kẹta jẹ ẹka ìgbìmò aṣòfin ti ìjọba ìpínlè Eko ti wọn ṣe ifilọlẹ rẹ ni Oṣu Kini ọjọ kerindinlogun, ọdun 1992, ti apejọ náà si ṣiṣẹ títí di ọjọ 1 Oṣu Karùn-ún ọdun 1999. .[1] Apejọ náà jẹ alailẹgbẹ pẹlu awọn aṣoju 41 ti wọn yàn làti àgbègbè kọọkan ní ìjọba ìpínlè náa. Olori ile ìgbìmọ̀ aṣòfin kẹta ni Rt. Hon Shakirudeen Kinyomi tì igbá-kejì rẹ sì jẹ Hon Rasheed Adebowale.[2]Ojo keji osu kefa odun 2003 ni Ile igbimo asofin kerin ti bere, nigba ti Adeleke Mamora ti jade gege bi olori ile igbimo asofin.[3][4][5]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "The Parliament of Lagos, Nigeria - Parliamentary Detail". cpahq.com. Archived from the original on 18 April 2015. Retrieved 18 April 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "SHAKIRUDEEN .O. KINYOMI, ENGR". Nigeriannotables.com. Archived from the original on 14 September 2020. Retrieved 18 April 2015.
- ↑ Uganwa, Austin (2014). NIGERIA FOURTH REPUBLIC NATIONAL ASSEMBLY. ISBN 9781499088755. https://books.google.com/books?id=ICCiBQAAQBAJ&dq=former+lagos+speaker,+Olorunnimbe+Mamora&pg=PA134. Retrieved 18 April 2015.
- ↑ "Buhari to announce running mate today". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 16 February 2015. Retrieved 18 April 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "AJOMALE RETURNS AS APC CHAIRMAN IN LAGOS STATE". Encomium Magazine. Retrieved 18 April 2015.