Abidemi Sanusi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Abídèmí Sànúsí)

Àdàkọ:BLP primary sources

Abídèmí Sànúsí
Ọjọ́ìbíÈkó, Nàìjíríà
Orílẹ̀-èdèỌmọ Nàìjíríà
Ẹ̀kọ́Leeds University
Iṣẹ́Oǹkọ̀wé
Notable workÌwé-ìtàn Aròsọ tí àkọlé rẹ̀ ń jẹ́ Eyo, ìwé-ìròyìn, Kemi's Journal, Ìwé-ìtàn, Zack's Story of Life, Love and Everything, God has daughter's too

Abídèmí Sànúsí jẹ́ gbajúmọ̀ ìlúmọ̀ọ́ká oǹkọ̀wé ọmọ bíbí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí wọ́n bí sí Ìpínlẹ̀ Èkó

Ìgbésí-ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Abídèmí Sànúsí sí ìlú Èkó lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó kàwé lórílẹ̀ èdè England ní Leeds University.

Abídèmí ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọ ènìyàn, tí ó sìn ṣiṣẹ́ ìbánimójútó ìkànnì ayélujára fún àwọn oǹkọ̀wé.

Ìwé ìtàn àròsọ Kemi's Journal tí ó kọ lọ́dún 2005 ni ìwé àpilẹ̀kọ rẹ̀ àkọ́kọ́, lẹ́yìn náà ló kọ Zack's Story of Life, Love and Everythingàti God Has Daughters Too.[1] Ìwé-ìtàn-àròsọ tí ó kọ lẹ́yìn tí àkọlé rẹ̀ ń jẹ́ Eyo, tí ilé iṣẹ́ atẹ̀wé, WordAlive Publishers tẹ̀ jáde ní wọ́n yàn fún àmìn-ẹ̀yẹ tí Commonwealth Writers' Prizelọ́dún 2010.[2]

Àwọn ìwé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Eyo (2009)
  • Kemi's Journal (2005)
  • God Has Daughters Too' (2006)
  • Zack's Story of Life, Love and Everything (2006)

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Agbro Jr., Joe (2010-02-28). "Nigerian authors eye Commonwealth crown". Vintage Press Limited. Archived from the original on 2010-08-21.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "Commonwealth Writers’ Prize regional winners’ shortlist announced". Commonwealth Foundation. Archived from the original on 2010-04-02.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)