Jump to content

Abubakar Dahiru

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

 

Abubakar Dahiru je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà láti Ìpínlẹ̀ Kano, ni orílè-èdè Naijiria, ti a bi ni ọdún 1969. Ó sìn ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà orílẹ̀-èdè kẹwàá, tó ń ṣojú ẹkùn ìdìbò ìpínlẹ̀ Lafia/Obi.lábé ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress kí o to padà sí inú ẹgbẹ òṣèlú Social Democratic Party[1] [2]