Jump to content

Adefunmilayo Tejuosho

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Hon.
Funmi Tejuosho
Ọjọ́ìbíAdefunmilayo Smith
25 Oṣù Kẹta 1965 (1965-03-25) (ọmọ ọdún 60)
ìpínlè Èkó, Nàìjíríà
Orílẹ̀-èdèọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Orúkọ mírànOloori Adefunmilayo Tejuosho
Iléẹ̀kọ́ gíga
Iṣẹ́
Ìgbà iṣẹ́1997  present
Political partyẸgbẹ́ òsèlú All Progressives Congress
Olólùfẹ́Omoba Kayode Tejuosho
Àwọn ọmọ4

Adefunmilayo Tejuosho (orúko abiso rè ni Smith) tí a bi ní ọjọ́ karúndínlọ́gbọ̀n oṣù Kàrún ọdun 1965 jé òtòkùlú olósèlú ni Nàìjirià, o tun jé asoju agbegbe Mushin ní house of Assembly ìpinlè Eko, oun ni alaga house of assembly Eko ti o un rí si ètò owó.

Àárò Aye àti Èkó rè

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bi Tejuosho ni ipinle Eko si idile Ademola Smith,[1] O lo ilé-ìwé primari ti Yunifásitì Ìlú Eko, o lo ilé-ìwé Queens College fún ìwé Sekondiri, Eko o pari ìwé Sekondiri rè ni West Virginia, léyìn ìwé rè, o tèsíwájú láti gba àmì-èye ninú ìmò Biology ni yunifásitì ti West Virginia.[2] O pada gba àmì-èye ninú imo ofin ni Yunifásitì ti Buckingham. Tenuous gba àmì-èye Ph.D nínú ìmò ofin láti Yunifásitì ti ìlú Eko.[3]

Nigba isé agubaniro rè, o sise ni ilé-ìwé Queens College ti o ti jáde. Ni odun 2003, a yan sip láti soju house of Assembly ìpinlè Eko, nigba to wa nipo náà, o mu aba ofin wa lati dojuko oko nina iyawo ati iyawo nina oko. Àbá náà pada di ofin.

O fe Omoba Kayode Tejuosho ti idile ade Tejuosho ìpínlè Ogun , Nàìjíríà.[4] awon mejeji bi omo merin.

  1. Oladesu, Emmanuel (2014-05-12). "Who is next Lagos deputy governor?". The Nation Newspaper. Retrieved 2022-05-30.
  2. "Funmi Tejuosho" Check |url= value (help). Hyperleap. 1965-03-25. Retrieved 2022-05-30.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  3. "HON. FUNMI TEJUOSO LOSES FATHER". Encomium Magazine. 2022-05-30. Retrieved 2022-05-30.
  4. "Hon. Funmi Tejuosho enumerates what life has taught her at 49". Encomium Magazine. 2014-03-29. Retrieved 2022-05-30.