Adenike Oladosu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Adenike Oladosu
Oladosu in 2020
Ọjọ́ìbíAdenike Titilope Oladosu
30 Oṣù Kẹ̀sán 1994 (1994-09-30) (ọmọ ọdún 29)
Abuja, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànTitilope
Ẹ̀kọ́University of Agriculture, Makurdi
Iṣẹ́Activist And Ecofeminist
Ìgbà iṣẹ́2018–present
Gbajúmọ̀ fúnClimate activism
Awards22 diverse voices to follow on Twitter this Earth Day by Amnesty International.15 ambassador of the African youth climate hub.

Adenike Oladosu ( tí wọ́n bí ní 1994[1]) jẹ́ olùgbèjà fún agbègbè àláìléwu fún àwọn ènìyàn àwùjọ, ó sì tún jẹ́ olùgbèrò fún ìdaṣẹ́sílè ilé-ẹ̀kọ́ fún ojú-ọjọ́ tó tẹ́rùn ní oríléédè Nàìjíríà[2][3][4]. Ó tún ṣàfihàn ìṣe ojú-ọjọ́ àìléwu ní àwọn àpèjọ ilẹ̀ òkèèrè tí UN Climate Change Conference, World Economic Forum, àti Elevate Festival nió GRaz-Austria.[5]

Ní oṣù kejìlá, ọdún 2019, Oladosu kópa nínú ìpàdé COP25 ní Spain gẹ́gẹ́ bí i aṣojú àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà níbi tí sọ̀rọ̀ tó mú àwọn ènìyàn lọ́kàn nípa àyípadà ojú-ọjọ́ níilẹ̀ Áfríkà àti bí ó ṣe yí àwọn ayé padà.[6][7]

Ìgbésí ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Oladosu jẹ́ ọmọ ògbómọ̀ṣọ́ láti ìlú Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Nàìjíríà.[8] Ó kàwé ní Government Secondary School, Gwagwalada, Abuja. Ó sì tún tẹ̀ síwájú ní ilé-ẹ̀kọ́ Federal University of Agriculture, Markurdi níbi tí ó ti gba ìpò iyì àkókọ́ nínú èkọ́ Ọ̀rọ̀-ajé ajẹmọ́gbìn.[9][8][10]

Ní ọdún 2019, wọ́n yàn án fún ìpàdé àkọ́kọ́ ti UN lórí ọ̀rọ̀ nípa ojú-ọjọ́ ní New York. Pẹ̀lú ìdánimọ̀ UNICEF gẹ́gẹ́ bíi ọ̀dọ́ tó ń mú ìyípadà dé bá ìlú, ó ń darí àjọ kan tí wọ́n ń pè ní ILeadClimate.

Ní 2019, wọ́n yàn án fún ìpàdé UN Youth Climate àkọ́kọ́ tó wáyé ní New York. Kò ṣàjèèjì sí ìgbìmọ̀ UNICEF Nàìjíríà gẹ́gé bí i ọ̀dọ́ aṣèyàtọ̀, ó ń darí ìdàgbàsókè ìbílẹ̀ tí ń ṣe ILeadClimate, tó ń ṣègbè fún ìràpadà Lake Chad àti ìkópa àwọn ọ̀dọ́ nínú ìdájọ́agbègbè àláìléwu fún àwọn ènìyàn àwùjọ nípa ẹ̀kọ́.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Tsanni, Abdullahi (2019-06-11). "My fight for climate action has just begun – Adenike Oladosu". African Newspage (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-01-27. 
  2. Simire, Michael (2019-09-19). "Six Nigerian youth activists to attend UN Climate Summit". EnviroNews Nigeria - (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-01-26. 
  3. Watts, Jonathan (2019-09-19). "'The crisis is already here': young strikers facing climate apartheid" (in en-GB). The Guardian. ISSN 0261-3077. https://www.theguardian.com/environment/2019/sep/19/the-crisis-is-already-here-young-strikers-facing-climate-apartheid. 
  4. McCarthy, Joe. "12 Female Climate Activists Who Are Saving the Planet". Retrieved 22 January 2020.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  5. "Oladosu Adenike Titilope". YBCA (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-03-01. 
  6. Breeze, Nick. "Youth strikers march for climate justice". The Ecologist. Archived from the original on 26 January 2020. Retrieved 22 January 2020.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  7. ""We need climate action," urge Nigerian children". CNN (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-03-14. Retrieved 2021-01-21. 
  8. 8.0 8.1 "Meet Adenike Oladosu, A Climate Justice Activist And Eco-reporter" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-12-08. 
  9. Adebote, ‘Seyifunmi (2019-09-19). "Six Nigerian youth activists to attend UN Climate Summit". EnviroNews Nigeria - (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-01-26. 
  10. Tsanni, Abdullahi (2019-06-11). "My fight for climate action has just begun – Adenike Oladosu". African Newspage (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-01-27.