Jump to content

Aláàfin Ọbalokùn

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Obalokun fìgbà kan jẹ́ as an Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́. Àsìkò rẹ̀ jẹ́ èyí tó tó kún fún àlàáfíà àti ìgbé ayé ìrọ̀rùn.

Ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọmọbìnrin Alake tó jẹ́ ọmọ Ẹ̀gbá ni ìyá Obalokun Agana Erin.

Gẹ́gẹ́ bí ìtàn Ọ̀yọ́ ṣe fi lélẹ̀, ó wà ní ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú ọba Faranse tàbí ti Portugal.[1]

Aláàfin Àjàgbó ló jẹ́ oyè yìí, lẹ́yìn tó wàjà.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Johnson, Samuel (2011). History of the yorubas. Research Associates School. ISBN 0948390891. OCLC 841599526.