David Abioye

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
David Abioye
Ọjọ́ìbíDavid Olatunji Abioye
Oṣù Kẹta 11, 1961 (1961-03-11) (ọmọ ọdún 63)
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ẹ̀kọ́University of Ilorin
Olólùfẹ́
Mary Abioye (m. 1988)
Àwọn ọmọ3
Websitedavidabioye.org.ng

David Olatunji Abioye je omo Naijiria ti a bi ni March 11,1961o je onigbagbo, onkowe ati oniwaasu; oun niigbakeji adari ijo fun ijo olorun igbagbo aye kaakiri agbaye iyen Living Faith Church. [1] O je bisoobu ati oniwaasu agba ni ijo to wa ni Abuja eyi ti a n pe ni ilu Goseni ti o ni iwon omo ijo oke meji ati abo ti o n josin nibe.[2][3][4]

Ìgbésí ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bi I si ilu idile kan ni ipinle Kwara.[5] Abioye se igbeyawo pelu arabinrin Mary Abioye; won si bi omo meta: David Jr, Ruth ati Daniel.[6][7] O lo si ile eko giga yunifasiti ti ilu ilorin lati lo ko eko nipa imo ero iyen (mechanical engineering).[8] O sise olumo ni ile eko gbogbo nise ni Auchi iyen (open cast polytechnic,Auchi) ni odun 1985 fun odun kan

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Adekunle. "Love, Forgiveness panaceas to broken marriages, says Abioye". 
  2. "2019: Bishop David Abioye lists ways Nigeria is being islamized by Buhari, tells members who to vote". 
  3. "Interview with Bishop David Abioye, Senior Pastor Of Living Faith Church, Goshen City". Archived from the original on 2018-12-15. Retrieved 2023-12-07. 
  4. "Serving God is not for clerics alone, says Bishop Abioye". 
  5. Kolesnik, Kay (28 December 2017). "Life story of Bishop David Abioye". Legit.ng – Nigeria news. (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-02-16. 
  6. "About Bishop Abioye". Archived from the original on 2020-11-24. Retrieved 2023-12-07. 
  7. "About Bishop Abioye – David Abioye" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-02-16. 
  8. "Pastor Series 4; David Abioye- Apostolic Humility and Loyalty in the Service of Bishop Oyedepo". ModernGhana. Retrieved 2019-10-28.