Jump to content

Fẹ́mi Adébáyọ̀

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Femi Adebayo)
Fẹ́mi Adébáyọ̀
Fẹ́mi Adébáyọ̀
Ọjọ́ìbíLagos, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian (1978-present)
Iṣẹ́
  • Actor
  • Director
  • Producer
  • Politician
  • Lawyer
Ìgbà iṣẹ́1985-present (Ogun Ajaye)
Parent(s)Adebayo Salami

Fẹ́mi Adébáyọ̀ (tí wọ́n bí ní Ọjọ́ kọkànlélọ̀gbọ̀n oṣù Kejìlá ọdún 1973) [1] jẹ́ amòfin, gbajúmọ̀ òṣèré, olóòtú àti olùdarí sinimá àgbéléwò ọmọ bíbí Ìlọrin ni ìpínlẹ̀ Kwara. Bákan náà Fẹ́mi Adébáyọ̀, títí di ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún ọdún 2019 jẹ́ Olùdámọ̀ràn Pàtàki lórí àṣà, ìrìn-afẹ́ àti iṣẹ́-ọ̀nà fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara àná, Abdulfatah Ahmed. Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò, Adébáyọ̀ Sàlámì, tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ọ̀gá Bello.

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Adebayo ní ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n oṣù Kejìlá (Ọ̀pẹ) ọdún 1978 ní ìpínlẹ̀ Èkó, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Bàbá rẹ̀, Adebayo Salami (Oga Bello) náà jẹ́ òṣèré tíátà àti agbéréjáde,[2] tó jẹ́ ọmọ bíbí ìlú IlorinÌpínlẹ̀ Kwara.[3]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Femi Adebayo, Actor, Producer, Nigeria Personality Profiles". Nigeria. Retrieved 2019-12-13.
  2. "Femi Adebayo Celebrates Father, Oga Bello As He Clocks 70". Independent Newspaper Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 9 May 2022. Retrieved 23 July 2022.
  3. Adebayo, Femi (4 January 2015). "My mum is stricter than dad – Oga Bello's son". The Punch (Interview). Interview with Gbenga Adeniji. Archived from the original on 15 February 2015. Retrieved 16 February 2015. Unknown parameter |url-status= ignored (help)