Fẹ́mi Adébáyọ̀
Ìrísí
(Àtúnjúwe láti Femi Adebayo)
| Fẹ́mi Adébáyọ̀ | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | Lagos, Nigeria |
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigerian (1978-present) |
| Iṣẹ́ |
|
| Ìgbà iṣẹ́ | 1985-present (Ogun Ajaye) |
| Parent(s) | Adebayo Salami |
Fẹ́mi Adébáyọ̀ (tí wọ́n bí ní Ọjọ́ kọkànlélọ̀gbọ̀n oṣù Kejìlá ọdún 1973) [1] jẹ́ amòfin, gbajúmọ̀ òṣèré, olóòtú àti olùdarí sinimá àgbéléwò ọmọ bíbí Ìlọrin ni ìpínlẹ̀ Kwara. Bákan náà Fẹ́mi Adébáyọ̀, títí di ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún ọdún 2019 jẹ́ Olùdámọ̀ràn Pàtàki lórí àṣà, ìrìn-afẹ́ àti iṣẹ́-ọ̀nà fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara àná, Abdulfatah Ahmed. Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò, Adébáyọ̀ Sàlámì, tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ọ̀gá Bello.
Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Wọ́n bí Adebayo ní ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n oṣù Kejìlá (Ọ̀pẹ) ọdún 1978 ní ìpínlẹ̀ Èkó, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Bàbá rẹ̀, Adebayo Salami (Oga Bello) náà jẹ́ òṣèré tíátà àti agbéréjáde,[2] tó jẹ́ ọmọ bíbí ìlú Ilorin ní Ìpínlẹ̀ Kwara.[3]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Femi Adebayo, Actor, Producer, Nigeria Personality Profiles". Nigeria. Retrieved 2019-12-13.
- ↑ "Femi Adebayo Celebrates Father, Oga Bello As He Clocks 70". Independent Newspaper Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 9 May 2022. Retrieved 23 July 2022.
- ↑ Adebayo, Femi (4 January 2015). "My mum is stricter than dad – Oga Bello's son". The Punch (Interview). Interview with Gbenga Adeniji. Archived from the original on 15 February 2015. Retrieved 16 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help)
