Jump to content

Ibrahim Tanko

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Muhammad Tanko

Chief Justice of Nigeria
In office
25 January 2019  27 June 2022
AsíwájúWalter Samuel Nkanu Onnoghen
Arọ́pòOlukayode Ariwoola
Justice of the Supreme Court of Nigeria
In office
7 January 2007  27 June 2022
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí
Ibrahim Muhammad Tanko

31 Oṣù Kejìlá 1953 (1953-12-31) (ọmọ ọdún 72)
Giade, Northern Region, British Nigeria (now Giade, Bauchi State, Nigeria)

Ibrahim Muhammad Tanko [1](tí a bí ní ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n, oṣù kejìlá, ọdún 1953) jẹ́ adájọ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó sìn ní ilé-ẹjọ́ tí ó ga jù lọ láti ọdún 2006 wọ ọdún 2022, àti bíi adájọ́ àgbà ilẹ̀ Nàìjíríà láti ọdún 2019 títí ó fi fìwé ìfipòsílẹ̀ ráńṣẹ́ ní oṣù kẹfà ọdún 2022 nítorí àìlera rẹ̀. [2][3][4][5] Ó fìgbà kan jẹ́ adájọ́ ní ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn.[6][7]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayẹ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Tanko jẹ́ ọmọ Fulani tí a bí ní ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n, oṣù kejìlá, ọdún 1953 ní Doguwa-Giade tó jẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Ìpínlẹ̀ Bauchi, tó wà ní apá Àríwá ilẹ̀ Nàìjíríà. Ó lọ sí ilé-ìwé gírámà ti ìjọba ni ìlú Azare, níbi tí ó ti gboyè WAEC ní ọdún 1973 kí ó tó lọ sí Fáṣítì Ahmadu Bello níbi tí ó ti gboyè LL.B. nínú ẹ̀kọ́ òfin Islam ní ọdún 1980. Ó padà gboyè LL.M. àti Ph.D. nínú ẹ̀kọ́ òfin ní Fáṣítì kan náà ní ọdún 1985 àti 1998 bákan náà.

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "FULL LIST: Okonjo-Iweala, Abba Kyari... FG nominates 437 persons for national honours". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-10-02. Retrieved 2022-10-11.
  2. Nda-Isaiah, Jonathan (2022-06-27). "BREAKING: President Buhari Swears In Justice Ariwoola As Acting CJN" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-06-28.
  3. "Justice Tanko Muhammad Resigns As CJN". Channels Television. Retrieved 2022-06-27.
  4. "Chief Justice of the Supreme Court of Nigeria".
  5. "The Nation Newspaper - Latest Nigeria news update" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-10-07. Retrieved 2022-06-27.
  6. Tobi Adeyeye. "CJN removes 2 Supreme Court justices off election petition tribunal". The Herald. Archived from the original on 2016-03-04. Retrieved 2022-10-13.
  7. "Service chiefs, Soun, Osemawe, Oyegun, Omosexy, 292 others on national honours' list". tribune.com.ng. Archived from the original on 18 May 2015. Retrieved 30 April 2015. Unknown parameter |url-status= ignored (help)