Ladapo Ademola
Ìrísí
| Ladapo Ademola | |
|---|---|
| Reign | 1920–1962 |
| Coronation | 24 September 1920 |
| Predecessor | Oba Gbadebo I |
| Successor | Oba Adesina Samuel Gbadebo II |
| Spouse | Olori Tejumade Alakija Ademola, Lady Ademola |
| Issue | |
| Omoba Sir Adetokunbo Ademola and Omoba Adenrele Ademola, amongst others | |
| Father | Oba Ademola I |
| Mother | Olori Hannah Adeyombo Ademola |
| Born | 1872 Abeokuta |
| Died | December 27, 1962 |
| Burial | December 31, 1962 |
Ladapo Samuel Ademola KBE, CMG (1872-1962), tí a tún mọ̀ sí Ademola II (kejì), ni ó jẹ́ Aláké ti Abẹ́òkúta láti ọdún 1920 sí 1962. Ṣáájú kí a tó dé e ládé Aláké, Ọba Ademola wà nínú ètò Ẹgbẹ́ Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Ìjọba Ẹ̀gbá. Gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ Ẹ̀gbá, ó jẹ́ olórí olùkópa nínú ìjíròrò pẹ̀lú ìjọba amúnisìn ní Ìpínlẹ̀ Èkó ní ọdún 1889 fún ẹ̀tọ́ láti ṣe òpópónà ọkọ̀ ojú irin tí ń gba Egbaland kọjá.[1]
Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ The Christmas number of the Nigerian Daily Times, 1932. (1932). Lagos, Nigeria: W.A. P. 8