Lagos State Task Force on Human Trafficking

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Lagos State Taskforce on Human Trafficking
Ìdásílẹ̀2020
IbùjókòóLagos
Agency ExecutiveMr. Moyosore Onigbanjo (SAN)

Lagos state Task force against Human Trafficking (Ẹgbẹ́ Àgbófinró ti ìpínlẹ̀ Èkó tí ó lòdì sí gbígbé káàkiri èèyàn fún iṣẹ́ ibi tàbí láti tà wọ́n dànù) jẹ́ ẹgbẹ́ iṣẹ́-ṣíṣe ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ṣètò láti dojú kọ́ gbígbé káàkiri ènìyàn nípasẹ̀ ìlànà ibi àti ìrìnàjò láti kúrò ní ìlú ní ọ̀nà tí ò bámu. Gómìnà Aláṣẹ ti Ìpínlẹ̀ Èkó, Babajide Sanwo-Olu ṣe ìfilọ́lẹ̀ àyàn ẹgbẹ́-iṣẹ́ ti ìpínlẹ̀ lórí gbígbé káàkiri ènìyàn ní ilé Ìjọba ní ọjọ́ kẹjọ Oṣù kẹ́san, ọdún 2020, pẹ̀lú ìpinnu gbogbogbò ti ṣíṣàkóṣo ìdáhùn ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn apá kan sí ìdènà ti gbígbé káàkiri ènìyàn, fúnni ní ìwọlé sí ìdájọ́ fún àwọn olùfaragbá ti gbígbé káàkiri, ìbanirojọ́ ti àwọn oníjàjàjà fún ẹ̀tọ́ àti ìmúdára ìlànà ti ìmupadàbọ́sípò àṣeyọrí ti àwọn ìyókù sí ipò ti ara, ìmọ̀-ọ̀rọ̀ àwùjọ, iṣẹ́-ṣíṣe àti àlàáfíà ètò-ọ̀rọ̀. Ẹgbẹ́ iṣẹ́ yìí ti ń ṣe àtúnṣe ní àwọn ìpínlẹ̀ ìhà ìwọ̀ oòrùn gúúsù míràn ní Ilẹ̀ Nàìjíríà. [1][2][3]

Àwọn Ìtọ́ka Sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Komolafe, Kayode (2020-09-09). "Sanwo-Olu Inaugurates Task Force against Human Trafficking". THISDAYLIVE. Retrieved 2022-03-30. 
  2. "Sanwo-Olu sets up task force on human trafficking". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-09-08. Retrieved 2022-03-30. 
  3. "Nigeria: Lagos sets-up anti-trafficking task force". The Migrant Project - The Migrant Project provides information about migration, in multiple languages, to people on the move or considering migration. We help migrants make more informed decisions about their options based on trusted information. 2020-09-09. Retrieved 2022-03-30.