Mark Angel (aláwadà)

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Mark Angel (tí a bí ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún, ọdún 1991) jẹ́ ọ̀kan lára àwọn gbajúmọ̀ aláwàdà ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀ fún àwọn eré àwàdà Mark Angel Comedy Series ní orí ìkànnì YouTube, èyí tí òun àti àwọn ará ilé rẹ̀ bi Emmanuella Samuel,[1] àti "Aunty" Success Madubuike. Ìkànnì Mark Angel ni ìkànnì àwàdà àkókò ni Afrika làti ní olólùfẹ́ mílíọ̀nù kan.[2]

Ìpìlẹ̀ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Angel ní Port Harcourt, Rivers State, Nigeria ni ọdún 1991.[3] Yunifásítì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ gbà á wọlé fún ẹ̀kọ́ ìmò ìṣègùn òyìnbó sugbon àbúrò bàbá rè tí ó fé ràn án lọ́wọ́ papòdà ni ọdún kan náà, èyí mú kí ó má le tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀. Ó padà lọ sí orílè-èdè Índíà láti kó nípa yíyàwòrán fíìmù[4] kí ó tó padà sí Nàìjíríà láti ní ìmò si nípa iṣẹ́ náà ṣùgbọ́n kò rí isẹ́ tí ó ń san owó tí ó te lọ́rùn ní Nollywood. Ó bẹ̀rẹ̀ sí ń ṣe fíìmù ara rẹ̀ ní odun.[5] Ó jẹ́ olólùfẹ́ Chelsea FC.[6] Ó sì gbó èdè Igbo àti Yoruba.[7]

Àwọn Ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Chidimma, Eze (5 June 2017). "10+ Unbelievable Facts About Mark Angel Comedy". BuzzNigeria. Retrieved 19 February 2019. 
  2. "Emmanuella's Channel Is The First African Comedy Channel To Hit 1 Million Subscribers On YouTube". SilverbirdTV (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2 June 2017. Archived from the original on 28 March 2019. Retrieved 20 March 2019.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. Nenge, Katrine (1 October 2018). "Mark Angel's biography: interesting facts you should know". Legit.ng. https://www.legit.ng/1195391-mark-angels-biography-interesting-facts-know.html. 
  4. "I once cried on set – Mark Angel - Punch Newspapers". 13 February 2016. 
  5. "I once cried on set – Mark Angel". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 14 February 2016. Retrieved 20 March 2019. 
  6. "World Cup 2018". Mark Angel Comedy – via YouTube. 
  7. "Passion of Christ". Mark Angel Comedy – via YouTube.