Muhammad Garba

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Comrade

Muhammad Garba
Commissioner
Ministry of Information
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
2015
GómìnàAbdullahi Umar Ganduje
Press Secretary
Office of the Deputy Governor
In office
1999–2003
GómìnàRabiu Kwankwaso
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí22 Oṣù Kọkànlá 1964 (1964-11-22) (ọmọ ọdún 59)
Kano,
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress (APC)
EducationBA, MA
Alma materBayero University Kano
OccupationJournalist politician

Muhammad Garba jẹ́ oníṣẹ́ ìròyìn Nàìjíríà ,[1] àti òṣèlú láti ìpínlẹ̀ Kano tí ó jẹ́ Kọmísọ́nà fún ìkéde.[2] àti ẹgbẹ́ kọmití International Federation of Journalists. [3]

Ìpìlẹ̀ àti Ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Muhammad ní Ọjọ́ Kejìlẹ́lógún oṣù kọkànlá ọdún 1965 ní agbẹ̀gbẹ̀ Yakasi, Kano Principal tí of Ipinle Kano. Ó lọ sí ilé-ìwé àkọ́bẹ̀rẹ̀ kofa Nassarawa àti Teachers college ní Sumaila níbi tí ó ti gba àmì ẹyẹ kí ó tó tẹ̀síwájú ní Yunifásítì Báyéró, Kano.[4][5]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Umar, Salim (10 January 2020). "PROFILE: Muhammad Garba, the Kano State Government Imagemaker". Platinum Post News. Retrieved 19 March 2020. 
  2. "Kano: Ganduje retains some former commissioners in 'new cabinet'". Daily Trust. 13 October 2019. Retrieved 19 March 2020. 
  3. Triumphnews, The (15 November 2019). "Meet Kano's New Commissioners (I)". THE TRIUMPH. Retrieved 19 March 2020. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  4. "Malam Muhammad Garba". Kano. Kano state Official website. 13 June 2018. Archived from the original on 3 December 2020. Retrieved 19 March 2020. 
  5. Ibrahim, Umar (2 March 2020). "The Journey of a Versatile Journalist to the Peak". Platinum Post News. Retrieved 19 March 2020.