Nahzeem Olúfẹ́mi Mímìkò

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Nahzeem Olufemi Mimiko
Vice Chancellor of Adekunle Ajasin University
In office
4 January 2010 – 4 January 2015
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí1 May 1960
Ondo State, Nigeria

Nahzeem Olúfẹ́mi Mímìkò tí wọ́n bí ní ọjọ́ Kíní oṣù Karùn ún ọdún 1960, jẹ́ onímọ̀ nípa ètò ẹ̀kọ́ àti alákòóso àgbà tẹ́lẹ̀ rí ilé-ẹ̀kọ́ Yunifásítì Adékúnlé Ajáṣin,[1] tí ó jẹ́ ilé-ẹ̀kọ́ ti Ìpínlẹ̀ Òndó ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ilé-ẹ̀kọ́ àgbà tí àjọ tí United State Transparency International Standard (USTIS) sọ wípé ó wà lára àwọn ilé-ẹ̀kọ́ tó peregedé jùlọ ní ọdún 2014, lásìkò ìṣàkóso Fẹmi Mímìkò.[2] Olúfẹ́mi Mímìkò nìkan ni ó jẹ́ alákòóso àgbà ilé-ẹ̀kọ́ Fásitì tí wọ́n yàn lọ síbi ìjíròrò àpapọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó wáyé lásìkò ìṣàkòso Ààrẹ Goodluck Ebele Jonathan ní ọdún 2014.[3] Ó gbs ipò àṣẹ alákòóso àgbà ilé-ẹ̀kọ́ Adékúnlé Ajáṣin ní oṣù Kíní ọdún 2010. Ó jẹ́ ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ àjọ African and African-American Studies Associate, at Harvard University, Cambridge, MA, USA. [4]

Àwọn Ìtọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. No alternative to democracy – Prof Mimiko, Nigeria: Vanguard News Paper, 2010, retrieved 2014-08-03 
  2. US agency ranks AAUA best varsity [sic] in Nigeria, Nigeria: Tribune News Paper, 2014, archived from the original on 2014-08-11, retrieved 2014-08-03  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. Prof. Femi Mimiko: The only VC delegate, Nigeria: The punch News paper, 2014, archived from the original on 2014-08-08, retrieved 2014-08-04  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  4. Adekunle Ajasin university Vice Chancellor Mimiko caves to pressure and reinstates ASUU leader and Members, Nigeria: Sahara Reporters, 2014, retrieved 2014-08-03