Naira Marley

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Naira Marley
Ọjọ́ìbíAzeez Fashola
9 Oṣù Kàrún 1994 (1994-05-09) (ọmọ ọdún 29)
Agege, Lagos State, Nigeria
Iṣẹ́
  • Singer
  • songwriter
Musical career
Irú orin
InstrumentsVocals
Years active2014–present
LabelsMarlian Records[1]
Associated acts

Naira Marley tí orúkọ àbísọ rẹ̀ gangan ń jẹ́ Azeez Fáṣọlá, tí wọ́n bí lọ́jọ́ kẹsàn-án oṣù karùn-ún ọdún 1994 (9th May 1994) jẹ́ gbajúmọ̀ olórin àti oǹpilẹ̀kọ̀wé-orin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. [2]Òun ní Ààrẹ ẹgbẹ́ olólùfẹ́ àgàbàgebè rẹ̀ tí wọ́n ń pè ní "Marlians".[3][4] [5]

Ìgbà èwe àti ìkẹ́kọ̀ọ́ ré[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Naira Marley ní ìlú Agége ní Ìpínlẹ̀ Èkó lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Nígbà tí ó wà lọ́mọdún mọ́kànlá ní o dèrò ìlú òyìnbó, ní Peckam, lápá gúúsù London, lórílẹ̀-èdè Gẹ̀ẹ́sì.[6] Ó kẹ́kọ̀ọ́ ní Porlock Hall kí ó tó tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní Walworth School, níbi tí ó ti gbàwé ẹ̀rí General Certificate of Secondary Education. Naira Marley kàwé gbàwé ẹ̀rí tí ó ga jùlọ nínú ìmọ̀ okoòwò ní ilé-ẹ̀kọ́ Harris Academy ní ìlú Peckam Peckham. Ó tún kàwé gbàwé ẹ̀rí nínú ìmọ̀ òfin okoòwò ní ilé-ẹ̀kọ́ giga Crossways College tí wọ́n ń pè ní Christ the King Sixth Form College .[7]

Àtójọ àwọn orin rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Orin alájọkò[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Gotta Dance (2015)
  • Lord of Lamba (2019)

Orin aládàákọ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • "Issa Goal" (2017)
  • "Japa" (2018)
  • "Am I A Yahoo Boy" (2019)
  • "Opotoyi (Marlians)" (2019)
  • "Soapy" (2019)
  • "Puta" (2019)
  • "Mafo" (2019)
  • "Tesumole" (2019)
  • "Tingasa" (2019)

Àtòjọ àwọn àmìn-ẹ̀yẹ tí ó gbà àti àwọn tí wọ́n yàn án fún[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọdún Àmìn-ẹ̀yẹ Abala Olùgbàmìn ẹ̀yẹ Àbájáde Ìtọ́kasí
2020 Soundcity MVP Awards Ààyò àwọn olùwòran "Soapy" Gbàá [8]
Orin tó dára jù lọ́dún Wọ́n pèé
Orin tàkasúfèé tó dára jù Naira Marley Wọ́n pèé
2019 City People Music Awards Olórin-kùnrin tó dára jù lọ́dún náà Wọ́n pèé [9]
Orin àdúgbò tó dára jù "Soapy" Wọ́n pèé

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Augoye, Jayne (2 January 2020). "Naira Marley floats record label, signs four artistes". Premium Times. https://www.premiumtimesng.com/entertainment/music/370941-naira-marley-floats-record-label-signs-four-artistes.html. Retrieved 12 January 2020. 
  2. "Naira Marley: Tins you suppose know about Afeez Fashola aka Naira Marley". BBC. 21 May 2019. https://www.bbc.com/pidgin/tori-48347911. Retrieved 12 January 2020. 
  3. Okanlawon, Taiwo (29 December 2019). "Naira Marley premieres new dance moves in “Tesumole”". P.M. News. https://www.pmnewsnigeria.com/2019/12/29/naira-marley-premieres-new-dance-moves-in-tesumole. Retrieved 12 January 2020. 
  4. Abraham, Anthony Ada (9 November 2019). "Marlian Movement And Their Crazy Lifestyle". Leadership Newspaper. https://leadership.ng/2019/11/09/marlian-movement-and-their-crazy-lifestyle. Retrieved 12 January 2020. 
  5. "Naira Marley: VIDEO". 21 May 2020. https://mp4hdd.com. Retrieved 12 January 2020. 
  6. "Naira Marley, Career, Background, Biography". NotJustOk. https://notjustok.com/artists/naira-marley. Retrieved 12 January 2020. 
  7. "Naira Marley Net Worth, Biography, Cars, and Lifestyle". PunchyInfo. 12 December 2019. https://punchyinfo.com/naira-marley-net-worth-biography-cars-lifestyle. Retrieved 12 January 2020. 
  8. Alake, Motolani (12 January 2020). "Davido, Naira Marley, Burna Boy, Rema, Fireboy and the winners at the Soundcity MVP Awards 2020". Pulse NG. https://www.pulse.ng/entertainment/music/davido-naira-marley-burna-boy-rema-fireboy-and-the-winners-at-the-soundcity-mvp/6kfthnn. Retrieved 12 January 2020. 
  9. "#CityPeopleMusicAwards: Nominees List Out". City People Magazine. 25 October 2019. Retrieved 12 January 2020.