National Temple

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

 

Tẹmpili Orilẹ-ede jẹ aye ijọsin fún fún ijo Aposteli Nigeria ti o wa ni Olorunda-Ketu, Ipinle Eko . Aye ijosin náà le gbà tó ènìyàn 100,000.

Itan[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ni ọdun 1969, Apejọ Ọdọọdun fún àwon Lagos, Western ati Northern Area (LAWNA) eyiti o maa n waye ni Ebute Metta ni a se ní Orishigun, ilu kan ni Ketu nitori pé àwon ti óún wá fún apejo naa un pọ si. Ni ọdun 1970, a se Apejọ náà ni Olorunda-Ketu.[1]

Ni 1979, Alaga agbegbe LAWNA kinni, Oloogbe Olusoagutan SG Adegboyega fi ipilẹ ilé ti a wa mo si National Temple lelẹ. Ni ọdun 1994, Oloogbe Olusoagutan Samuel Jemigbon se ilọsiwaju kikọ ilè naa ni akoko rẹ gẹgẹ bi Alaga agbegbe LAWNA kẹta. [2]

A pari kíkó National Temple ní 19 November 2011 lábé idari Olusoagutan Gabriel Olutola eni tí o so pé "ilé náà jé ilé tí a fi adura kó"[3] and "o si jé iranleti isokan ìjo." Ilé náà le gbà tó eniyan ogorun egbèrún(100,000)[4]

Àwon ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Temple". tac-lawna.org. January 6, 2013. Archived from the original on January 6, 2013. Retrieved September 12, 2022.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. Empty citation (help) "National Temple Overview". Archived from the original on 6 January 2013. Retrieved 12 July 2015.
  3. Udodiong, Inemesit (August 14, 2017). "11 things that are never going to change about this denomination". Pulse Nigeria. Retrieved September 12, 2022. 
  4. Nation, The (August 3, 2018). "We're repositioning at 100, says Apostolic Church The Nation Newspaper". The Nation Newspaper. Retrieved September 12, 2022.