Jump to content

Olajumoke Okoya-Thomas

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Olajumoke Okoya-Thomas
Aṣojú ní ilé ìgbìmò Asòfin kékeré
In office
2003–2007
Aṣojú ní ilé ìgbìmò Asòfin kékeré
In office
2007–2011
Aṣojú ní ilé ìgbìmò Asòfin kékeré
In office
29 April 2011  29 April 2015
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí20 Oṣù Kínní 1957 (1957-01-20) (ọmọ ọdún 69)
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAPC
OccupationPolitician

Olajumoke Abidemi Okoya-Thomas jé omo ile igbimo asojú teleri,[1] o soju Lagos island/Federal constituency ti ìpinlè Eko labé egbe oselu All Progressive Congress(APC), o lo sáà meta nípò asojú.

Àárò Ayé àti Èkó rè

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olajumoke jé omo Oloye Molade Okoya-Thomas[2] eni to jé Asoju Oba Eko, a bi ní 20 January 1957. O gba Diploma ní Senior Managers nínú ìmò Government ní yunifásitì Harvard àti àmì-èye diploma nínú ìmò sec. admin láti Burleigh College.[3]

Olajumoke Okoya-Thomas wó ipò asoju fun ìgbà keta ní 29 April 2011. Àwon nkan tó nife sí ni riran awon obinrin àti omodé lowo lawujo.[4] O jé alaga teleri fún ìgbìmò tó ún rí sí òrò ewon.[5]

Ni odun 2013, Olajumoke gbero láti se òfin pipa dandan fún àwon obinrin láti fomu fún àwon omo won. A ò padà so igbimo di òfin toriwipe àwon ìgbìmò asojú náà rò pé kò tó láti pon dandan fún àwon obinrin láti fún àwon omo loyan, bi o rile jé wipe wón gbà bé wipe fifun omo loyan.[6] Òun tún ni adari àwon obinrin egbé oselu All Progressive Congress(APC), èka ìpinlè Eko.[7]  

  1. "Public offices held by Olajumoke Abidemi Okoya-Thomas in Nigeria". Citizen Science Nigeria. 2011-05-29. Retrieved 2022-05-30.
  2. "Jumoke Okoya Runs Into Political Trouble For Eyeing Remi Tinubu's Senatorial Seat! - SocietyNowNg.com ::: News from the Nigerian Society, Entertainment, Movie, Music, Fashion, Parties, Interviews...". societynowng.com. 2014-03-31. Archived from the original on 2014-03-31. Retrieved 2022-05-30. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. "Olajumoke Okoya-Thomas". Nnu.ng - Nigeria News Update. 2019-03-16. Archived from the original on 2022-02-23. Retrieved 2022-05-30.
  4. "ShineYourEye". ShineYourEye. Retrieved 2022-05-30.
  5. "Reps Reject Bill On Exclusive Breast Feeding". Channels Television. 2013-01-29. Retrieved 2022-05-30.
  6. "Lagos APC: Jumoke Okoya-Thomas task party leaders on Kemi Nelson's conduct". National Daily Newspaper. 2018-09-02. Archived from the original on 2023-06-05. Retrieved 2022-05-30.