Jump to content

Oluchi Okorie

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Oluchi Okorie
No. 7
Forward, center
Personal information
Born28 Oṣù Kẹjọ 1981 (1981-08-28) (ọmọ ọdún 44)
Lagos, Nigeria
NationalityNigerian
Career information
CollegeTexas State Bobcats

Oluchi Mercy Okorie tí a bí ní ọjọ́ kejìdínlọgbọ̀n osù kẹjọ ọdún 1981 ní Ìlú Èkó jẹ́ agbábọ́ọ̀lù sínú agbọ̀n ti orílẹ̀-ède Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí tí ó gbábọ́ọ̀lù fún First Bank BC àti ẹgbẹ́ orílè-èdè Nàìjíríà. Ó ṣe aṣojú Nàìjíríà ní bi 2005, 2006 àti 2007 FIBA Africa Championship.[1][2]

iṣẹ́ Ìdárayá síse

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Láti ogúnjọ́ sí ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n Oṣù kejìlá, ní gbọ̀ngàn eré ìdárayá inú ilé ní Abuja, Nàìjíríà tí wọ́n ti gbàlejò FIBA Africa Championship fún àwọn obìnrin ní ọdún 2005 . Níbi ayeye náà, Oluchi ló sojú orílẹ̀-ède Nàìjíríà tó sì gba ààmì ẹ̀yẹ wúrà.[3]

Ní bi 2006 FIBA Africa Women's Club Champions Cup èyí tí ó kópa, Oluchi gba ààmì ẹ̀yẹ idẹ.

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]