Oluchi Okorie
Ìrísí
| No. 7 | |
|---|---|
| Forward, center | |
| Personal information | |
| Born | 28 Oṣù Kẹjọ 1981 Lagos, Nigeria |
| Nationality | Nigerian |
| Career information | |
| College | Texas State Bobcats |
Oluchi Mercy Okorie tí a bí ní ọjọ́ kejìdínlọgbọ̀n osù kẹjọ ọdún 1981 ní Ìlú Èkó jẹ́ agbábọ́ọ̀lù sínú agbọ̀n ti orílẹ̀-ède Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí tí ó gbábọ́ọ̀lù fún First Bank BC àti ẹgbẹ́ orílè-èdè Nàìjíríà. Ó ṣe aṣojú Nàìjíríà ní bi 2005, 2006 àti 2007 FIBA Africa Championship.[1][2]
iṣẹ́ Ìdárayá síse
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Láti ogúnjọ́ sí ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n Oṣù kejìlá, ní gbọ̀ngàn eré ìdárayá inú ilé ní Abuja, Nàìjíríà tí wọ́n ti gbàlejò FIBA Africa Championship fún àwọn obìnrin ní ọdún 2005 . Níbi ayeye náà, Oluchi ló sojú orílẹ̀-ède Nàìjíríà tó sì gba ààmì ẹ̀yẹ wúrà.[3]
Ní bi 2006 FIBA Africa Women's Club Champions Cup èyí tí ó kópa, Oluchi gba ààmì ẹ̀yẹ idẹ.
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Oluchi Mercy Okorie profile, African Cup for Women's Champion Clubs 2006". FIBA.COM. Retrieved 2020-11-13.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]Àdàkọ:Cbignore
- ↑ "Oluchi Okorie Basketball Player Profile, MKS MOS Karkonosze Jelenia Gora, News, 2Liga, Career, Games Logs, Best, Awards - eurobasket". Eurobasket LLC. Retrieved 2020-11-17.
- ↑ "Schedule & results". FIBA.com. Archived from the original on 21 September 2013. Retrieved 2020-11-13. Unknown parameter
|url-status=ignored (help)