Jump to content

Olusola Steve Fatoba

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Olusola Gbadura Steve Fatoba je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà . O jẹ ọmọ ẹgbẹ ti o nsójú àgbègbè Ado Ekiti/Irepodun-Ifelodun ni Ile Awọn Aṣoju ṣòfin àgbà.[1][2]

Ìgbésí àyè ibẹrẹ àti Ìrìnàjò òṣèlú

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olusola Steve Fatoba ni wọ́n bí ní ọjọ kẹwàá oṣù kẹwàá ọdún 1967, o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Ìpínlẹ̀ Ekiti . Ni ọdun 2019, o ṣe rọ́pò Sunday Oladimeji wọn dibo yàn si ile ìgbìmò aṣòfin apapọ. Wọn tún yàn ni ọdún 2023 fun saa kejì labẹ ẹgbẹ òṣèlú All Progressive Congress (APC). Ó tí sìn nígbà kàn rí gẹ́gẹ́ bí alámójútó ìgbìmò Iṣẹ́, Ìjọba ìbílè Ado, Èkìtì. [1][3]

  1. 1 2 "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-04.
  2. "10th National Assembly Members - Voter - Validating the Office of the Electorate on Representation". orderpaper.ng. Retrieved 2025-01-04.
  3. "National Assembly | Federal Republic of Nigeria". nass.gov.ng. Retrieved 2025-01-04.