Òṣogbo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Osogbo)
Ataoja of Oshogbo-min


Òṣogbo (2015)
Location of Osogbo in Nigeria
Ìtàn ṣókí nípa Ìlú Òṣogbo láti ẹnu ọmọ bíbí Òṣogbo

Òṣogbo jẹ́ ìlú ńlá kan ní ìpílẹ̀ Ọ̀ṣun ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, bákan náà ni ó jẹ́ olú ìlú fún ìpínlẹ̀ náà ní apá ìwọ̀ Oòrùn ilẹ̀ Nàìjíríà. Ọ̀gbẹ́ni Gbóyèga Òyètọ́lá ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun lọ́wọ́lọ́wọ́. Òṣogbo di olú ìlú fụ́n Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ní ọdun 1991.[1] Bákan náà ni ó tún jẹ́ olú ilé-iṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ fún ìlú Òṣogbo, tí ilé-iṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ náà sì wà ní Òke Báálẹ̀, nígbà tí ìjọba ìbílẹ̀ Ọlọ́rundá ń ṣojú agbègbè Ìgbóǹnà nílú Òṣogbo.[1][2]

Àwọn ìtọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àdàkọ:Oluilu ipinle Nàìjíríà

  1. 1.0 1.1 Jiboye, Adesoji David (1 March 2014). "Significance of house-type as a determinant of residential quality in Osogbo, Southwest Nigeria" (in en). Frontiers of Architectural Research 3 (1): 20–27. doi:10.1016/j.foar.2013.11.006. ISSN 2095-2635. http://www.sciencedirect.com/science/article/pii/S2095263513000812. 
  2. "Supreme Court affirms Gboyega Oyetola's election as Osun Governor". Premium Times Nigeria. 2019-07-05. Retrieved 2019-09-18.