Sheik Muyideen Àjàní Bello
Sheik Muyideen Àjàní Bello tí wọn bí ní ọdún 1940 tí ó sì papò dà ní ọjọ́ Jímọ̀ ọjọ́ kẹfà oṣù kejìlá ọdún 2024, jé Àfáà àgbà, oní wáàsí lójú ònà ẹ̀sìn Mùsùlùmí, àti ọmọ bíbí ìlú Ìbàdàn.
Ìgbé ayé rè
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Wọn bi Muyideen Bello sinu ẹbí Alhaji Bello Àjànì àti Alhaja Ubaidat Bello ninu agbolé Arólú, ní ita Olúkòyí, ni ilú Ìbàdàn. Sheik Muyideen Àjàní Bello bèrè isé wáàsí ìta gbangba nígbà tí ó wà ní omo odún méwàá léyìn tí ó ti kó nípa ìmò Alùkùránì lábé bàbá rè tí ó jé Àfáà àgbà nílùú Àgberígbe tí ó jé ìletò kan nílùú Ìwó. Lásìkò tí ó wà ní omo odún mésàán ni ó lo gbé lódò àbúrò bàbá rè tí òun náà náà jé Àfáà oníwáàsí ìta gbangba tí ó sì tún nílé kéwú nílùú Ìbàdàn.[1]
Ètò èkó rè
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Léyìn tí Muyideen dé òdò àbúrò bàbá rè, ó bèrè ilé iwé alákòó-bèrè níbàdàn, tí o sì tún n fojú sékòó Àlùkùránì ní ìròlé tí ó bá dé láti ilé iwé rè. Léyìn èyí, ó lo sí ilé èkó girama àtivilé èkó àwon olùkó (N.C.E). Ó se isé olùkóni ní ilé iwé Ansa-ru-deen College tí ó wà ní ìlú Sakí ní ìpínlè Òyó. Ó tún se isé olùkó ní ìwé girama Abeokuta,níbi tí ó to kó èkó àti èkó Biology.[2]
Àwon ìtóka sí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Opeyemi, Oyebajo (2018-04-20). "THE FAITHFUL – The birth and life of sheikh Muyideen Ajani Bello Part 1". HappeningsTV. Retrieved 2018-11-07.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ "Sheikh Muyideen Ajani Bello". Encomium Magazine. 2017-12-16. Retrieved 2018-11-07.