Temi Balogun

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Temi Lola Balogun tí orúkọ inagi rẹ̀ jẹ́ TaymiB jẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Òun sì ní olùgbé sílẹ̀ ètò Skinny Girl in Transit. Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ Queen's College ni ìlú Èkó. Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga tí Nottingham Trent University[1]. Òun àti àbúrò rẹ̀ jọ kọ orin Soyinka's Afro ní ọdún 2009.[2] Balogun di atọ́kun fún ilé iṣẹ́ Cool Fm ni ìlú Èkó.[3] Ó gbé eré Things Men Say jáde ní ọdún 2017.[4][5] Ní ọdún 2019, òun àti N6 jọ ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nurọ̀ fún olórin Cardi B nígbà tí ó wá sí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà[6][7]. Tèmilola jẹ́ ìyàwó fún Timi Akinmuda, wọ́n sì ti bí ọmọ méjì.[8]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Judges - Africa Connected". www.africaconnected.com. Archived from the original on 2020-01-30. Retrieved 2020-02-29. 
  2. BellaNaija.com (2009-11-05). "Who Is…Soyinka’s Afro". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-02-29. 
  3. "Cool FM". Streema. Retrieved 2020-02-29. 
  4. "Temilola Akinmuda The Creative". guardian.ng. Archived from the original on 2020-02-29. Retrieved 2020-02-29. 
  5. Tv, Bn (2017-09-19). "It's here! Watch Episode 1 of Box TV's "Things Men Say" featuring Bollylomo & Joules". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-02-29. 
  6. "Cool FM hosts Cardi B in first ever live radio interview in Nigeria". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-12-07. Retrieved 2020-02-29. 
  7. Salaudeen, Aisha. "Cardi B is set to perform for the first time in Nigeria and Ghana". CNN. Retrieved 2020-02-29. 
  8. CoolFM, StayBusy Tech For. "Cool FM Nigeria | #1 Hit Music Station". CoolFM (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-02-29.