Jump to content

Titilope Gbemisola Akosa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Titilope Gbemisola Akosa
Ọjọ́ìbíTitilope Gbemisola Ngozi Akosa
Lagos, Nigeria
Iṣẹ́
Ìgbà iṣẹ́2004–present
Gbajúmọ̀ fún

Titilope Gbemisola Akosa tí gbogbo ènìyàn mọ́ sì Titolope Akosa jẹ agbejọ́rọ̀ ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà[1]. Òun ni olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Titi Akosa & Co ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Ní ọdún 2015, ó jẹ́ agbenuso fún àwọn obìnrin lórí ètò tí àkọlé rẹ jẹ́ Towards a Gender Responsive Green Climate Fund in Africa ní ibí ayẹyẹ Paris Climate Treaty.[2][3][4][5][6]

Ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Títí sì ìlú Èkó, ibè sì ni ó dàgbà sì. Ó gboyè nínú ìmò òfin láti ilé ẹ̀kọ́ gíga tí Lagos State University, ó sì tẹ̀ síwájú sí ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Lagos níbi tí ó tí gbà masters rẹ̀.

Akosa dá ilé iṣẹ́ tirẹ̀ tí ó pè ní Títí Akosa & Co pẹ̀lú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ mìíràn, òun sì ni olórí àti olùkọ́ni onímòràn nípa òfin fún ilé iṣẹ́ náà[7].

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]