Yunifásítì ìlú Abùjá

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti University of Abuja)
Fáṣítì Ìpínlẹ̀ Abuja.
Yunifásítì ìlú Abùjá

Yunifásítì ìlú Abùjáyunifásítì ní ìlú Abuja, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. A da kalè ní odun 1988 [1] bí o tile jé pe àwon akeko àkókó se ayeye ìwolé ní odùn 1990 tí isé sì bere ní odún na.[1] Orúko Olori yunifásitì tí ìlú Abuja lówólówó ní Òjògbón Abdulrasheed Na'Allah [2], ìjoba rè bèrè ní ojo kini, osù keje, odun 2019(July 1, 2019)[3]. Yunifásitì Abújá ni ogba méjì(Main campus àti mini campus). Mini campus wà ni ìlú Gwagwalada, main campus sì wà ni ona Àbújá-airpot. Yunifásitì ìlú Àbújá ní ilè tí o kojá egbèrún mokanla hectare ile(over 11, 000 hectares) èyi tí o mu won jé yunifásitì kejì tí ó ní ilè jù ní Nàìjíríà [4].

Ile ikawe[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A da ile ikawe Yunifisiti naa kale ni odun 1988 lati gbaruku ti kiko,omimo ari iwadi eyiuti o je okan lara awon ete Yunifisiti ilu Abuja nipa pipese awon ohun ti akeko nilo fun eko ni lort ero ayejujara ati iwe ti eniyan le dimu.[5]

Àwọn Itokasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "About - University of Abuja". UNIABUJA. Archived from the original on 2022-03-01. Retrieved 2022-03-01. 
  2. Report, Agency (2019-07-01). "University of Abuja gets new VC". Premium Times Nigeria. Retrieved 2022-03-01. 
  3. "UniAbuja appoints Prof. Na’ Allah as new VC - Nigeria and World News". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. 2019-07-04. Retrieved 2022-03-01. 
  4. Olusunle, Tunde (2021-11-20). "The Unilorin 'better by far' basket and one bad apple". TheCable. Retrieved 2022-03-02. 
  5. "UNIVERSITY OF ABUJA LIBRARY's open resources | University of Abuja Open Education Resources (OER)". oer.uniabuja.edu.ng (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2022-12-30. Retrieved 2022-12-30.