Oluremi Tinubu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Oluremi Tinubu ( tí a bí ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù kẹsàn-án ọdún 1960) jẹ́ olóṣèlú ọmọ , bíbí Ìpínlẹ̀ Ògùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1] Ó jẹ́ Ìyàwó Bọ́lá Ahmed Tinúbú, ẹni tí ó jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó ní ọdún 1999 sí ọdún 2007. Rẹ̀mí tún jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ilé-aṣòfin-Àgbà lowolowo (Senator) tí ó ń ṣojú fún Ẹkùn Àárín gbùngbùn Ìpínlẹ̀ Èkó,fún ìgbà Ìkẹ́ta ní Ilé Alàgbà Nàìjíríà.[2]

Ibèrè ayé àti èkó[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olúrèmí Tinúbú jé àbíkéhìn nínú omo méjìlá; ó sì dàgbà ní ìpínlè Ogun State.

Alufa Oluremi Tinubu beere eko re ni ile-iwe Our Lady of Apostles Secondary School Ijebu-Ode ni bi ti won gba West African Senior Secondary School Certificate Exam (WASSCE) in 1979, Olúrèmí ka èkó ilé-ìwé gíga ní University Ifè, àti Adeyemi College of Education.and PGD from The Redeemed Christian bible college in 2010[3]

Isé Olósèlú[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olúrèmí Tinúbú je arabinrin àkókó tì'lu èkó nígbà ti oko re, Bólá Tinúbú, je gomina. Beeni o so da New Era Foundation, eyi to was fun idagbasoke ati igbega awon odo, ati lati kpolongo imototo awujo.

Nigbati arabinrin Tinubu wole fun ise oselu ,arinyunjiyun sele titi to fi de odo awon Ile-igbimọ Idibo Ile asofin -Arabin Tinubu se aseyori nibe osi wole sibe sibe ni 2012.

Tinubu wa lara awon ogorun igbimo ti won diibo fun ni 2015. Mefa lara won je obinrin . Oruko awon obinrin naa ni Stella Oduah, Uche Ekwunife, osujo fun ilu Anambra, Fatimat Raji Rasaki, Rose Okoji Oko and Binta Garba[4]. Ati igba naa arabinrin Tinubu ti ó gbé ìjókòó ilé ìgbimọ̀ rẹ̀ , osujo fun Lagos Central, ṣiṣe ni akoko kẹta rẹ ni ọfiisi

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Themes, AccessPress (2019-08-12). "About Oluremi – Oluremi Tinubu @ Senate". Oluremi Tinubu @ Senate. Archived from the original on 2019-09-25. Retrieved 2019-09-25. 
  2. "Oluremi Tinubu". Wikipedia. 2012-05-20. Retrieved 2019-09-25. 
  3. "Remi Tinubu Biography and Detailed Profile". Politicians Data. 2018-05-28. Archived from the original on 2022-07-05. Retrieved 2022-08-24. 
  4. Obiajuru, Nomso (2015-05-29). "MEET The 6 Female Senators In 8th National Assembly (PHOTOS)". Legit.ng - Nigeria news. Retrieved 2022-08-24.