Ìjọba Dahomey

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ìjọba Dahomey

c. 1600–1904
Flag of Ìjọba Dahomey
Top: Flag of Béhanzin (c. 1890c. 1894)
Bottom: Flag of Ghezo (1818–1858)
Coat of arms (c. 1890–c. 1894) ilẹ̀ Ìjọba Dahomey
Coat of arms (c. 1890c. 1894)
Ìjọba Dahomey ní ọdún 1894, ó wà ní ibi tí Republic of Benin wà lóní ní ìwọ̀ oòrùn Áfíríkà.
Ìjọba Dahomey ní ọdún 1894, ó wà ní ibi tí Republic of Benin wà lóní ní ìwọ̀ oòrùn Áfíríkà.
StatusÀdàkọ:Infobox country/status text
OlùìlúAbomey
Àwọn èdè tówọ́pọ̀Fon
Ẹ̀sìn
Vodun
Orúkọ aráàlúDahomean
ÌjọbaMonarchy
Ahosu (King) 
• c. 1600–1625 (first)
Do-Aklin
• 1894–1900 (last)
Agoli-agbo
Ìtàn 
• Aja settlers from Allada settle on Abomey Plateau
c. 1600
• Dakodonu begins conquest on Abomey Plateau
c. 1620
• King Agaja conquers Allada and Whydah
1724–1727
• King Ghezo defeats the Oyo Empire and ends tributary status
1823
• Annexed into French Dahomey
1894
• Títúká
1904
Ìtóbi
1700[1]10,000 km2 (3,900 sq mi)
Alábùgbé
• 1700[1]
350,000
OwónínáCowrie
Àdàkọ:Infobox country/formernext
Today part ofBenin

Ìjọba Dahomey ( /dəˈhmi/) jẹ́ ìjọba kan ní ìwọ̀ oòrùn Áfíríkà tí orílẹ̀ èdè Benin wà lọ́jọ́ òní. Ìjọba náà wà láti ọdún 1600 títí di 1904. Wọ́n kó Dahomey sí orí òkè Abomey, ìjọba náà di alágbára lágbègbè rẹ̀ ní àwọn ọdún 1700s, wọ́n sì ségun àwọn ilẹ̀ tí ó wà ní gúúsù wọn láti tan ilẹ̀ wọn, àwọn ilẹ̀ bi Whydah ti ìjọba Whydah tí etí odò Atlantic èyí tí ó mú wọn ní àṣẹ sí àwọn ilẹ̀ tí wọ́n ti ń ṣe triangular trade.

Láàrin àwọn ọdún 1800s, ìjọba Dahomey di alágbára àgbègbè náà kí ó tó di pé Ìpínlẹ̀ Oyo.[1]

Àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè ní orílẹ̀ Europe tí ó wá sí ilẹ̀ náà kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ nípa rẹ̀. Ìjọba Dahomey jẹ́ alágbára ní agbègbè náà tí ọ̀rọ̀ ajé wọn dá lórí Okoẹrú.

Ìjà ilẹ̀ padà bẹ̀rẹ̀ sí ń ní bọ́yọ̀ láàrin orílẹ̀ èdè France àti ìjọba náà, èyí fa Ìjà Franco-Dahomean àkọ́kọ́ ní ọdún 1890, orílẹ̀ èdè Faransé sì ségun ogun náà. Ìjọba náà padà lólẹ̀ ní ọdún 1894 nígbà tí àwọn ọmọ ogun Faranse pa ọba Dahomey ní ogun Franco-Dahomean kejì.

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 Heywood, Linda M.; John K. Thornton (2009). "Kongo and Dahomey, 1660–1815". In Bailyn, Bernard & Patricia L. Denault. Soundings in Atlantic history: latent structures and intellectual currents, 1500–1830. Cambridge, MA: Harvard University Press.