Ghezo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ghezo
King of Dahomey

A depiction of King Ghezo in a 1851 publication
Reign 1818–1859
Predecessor Adandozan
Successor Glele
Father Agonglo
Died 1859 (1860)
The Royal flag of Ghezo

Ghezo, tí sípẹ́lì rẹ̀ tún jẹ́ Gezo, jẹ́ ọba ilẹ̀ Dahomey, (èyí tó ti di ìlú Benin báyìí) láti ọdụ́n1818 títí wọ 1859. Ghezo rọ́pò ẹ̀gbọ́n rẹ̀ tí ń jẹ́ Adandozan (tó jọba láti ọdún 1797 títí wọ ọdún 1818) gẹ́gẹ́ bí i ọba látàri ìsọ̀tè tó wáyé pẹ̀lú ìànlọ́wọ́ àwọn olówò ẹrú ilẹ̀ Brasil, ìyẹn Francisco Félix de Sousa. Ó jọba lóri ìlú náà lásìkò tí rúdurùdu gbilẹ̀ ní ilẹ̀ náà, pẹ̀lú ìdíwọ àwọn èbúté lóríṣiríṣi tó ti ọwọ́ àwọn aláwọ̀ funfun wá, láti dẹ́kun Atlantic slave trade.[1]

Ghezo ló fòpin sí sísan ìṣákọọ́lẹ̀ sí Oyo Empire.[2] It is quite likely that the initial struggle was more violent than this story relates.[3] Lẹ́yìn náà, ó gbógun ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ olówò ẹrú, ní ìbámu láti dẹ́kùn òwò náà. Wọ́n pa Ghezo ní ọdún 1859, ọmọ rè Glele sì jọba.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Bay, Edna G. (1998). Wives of the Leopard: Gender, Politics, and Culture in the Kingdom of Dahomey. University of Virginia Press. ISBN 0-8139-1792-1. 
  2. Akinjogbin, I.A. (1967). Dahomey and Its Neighbors: 1708-1818. Cambridge University Press. 
  3. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named Bay2