Abubakar Amuda-Kannike
Ìrísí
Abubakar Amuda-kannike | |
|---|---|
| Member of the House of Representatives | |
| In office 2015–2019 | |
| Constituency | Ilorin East/Ilorin South |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | Kwara State, Nigeria |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Occupation | Politician |
Abubakar Amuda-kannike je olóṣèlú ọmọ orile-ede Nàìjíríà lati Ìpínlẹ̀ Kwara . O ṣe aṣoju àgbègbè Ila-oorun / Ilorin South gẹgẹbi ọmọ ẹgbẹ ti Ile-igbimọ Aṣoju, Apejọ Orilẹ-ede, lati ọdún 2015 si 2019. [1] Bákan naa lo tun je Komisana fun ise ati oko ni Ìpínlẹ̀ Kwara. [2]