Adebo Ogundoyin

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Àdàkọ:Use Nigerian English

Rt. Hon.

Adebo Edward Ogundoyin
Speaker of the Oyo State House of Assembly
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
June 2019
ConstituencyIbarapa East
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí17 Oṣù Kejì 1987 (1987-02-17) (ọmọ ọdún 37)
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúPeople's Democratic Party
(Àwọn) olólùfẹ́Olamidun Majekodunmi - Ogundoyin
ÌyáJustina Iyabo Ogundoyin
BàbáAdeseun Oguntona Ogundoyin
EducationBabcock University
Occupation

Adebo Edward Ogundoyin (tí wọ́n bí ní17 February 1987) jẹ́ olóṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Òun ni abẹnugan ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin kẹsàn-án ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Ó tún jẹ́ aṣòfin tí ń ṣojú agbègbè Ìlà-oòrùn Ìbàràpá lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ òṣèlú Alábùradà (Peoples Democratic Party PDP).[1][2][3][4]

Ó gba ipò ní 10 June 2019.[2]

Ìgbésí ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Adebo Edward Ogundoyin wá láti ẹkùn-ìdìbò Ìlà-oòrùn Ìbàràpá, ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní ilé-ẹ̀kọ́ Fásitì Babcock (Babcock University).[5] Wọ́n dìbò yàn án láti ṣojú ẹkùn-ìdìbò Ìlà-oòrùn Ìbàràpá, wọ́n sì tún dìbò yàn án gẹ́gẹ́ bí abẹnugan ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin láìní alátakò, ní ọjọ́ Ajé 10 June 2019.

A second timer, he was first elected into the 8th house of Assembly in 2018 on the platform of the Peoples Democratic Party (PDP) after he won the bye-election, which was held after the death of the former Speaker, Rt. Hon. Michael Adeyemo, who died on Friday, 27 April 2018.[6]

Family background[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Adebo Ogundoyin is one of the sons of the late foremost philanthropist and industrialist, Chief Adeseun Ogundoyin. He lost his father, Adeseun Ogundoyin, in 1991 at four years old. Chief Adeseun Ogundoyin, Alhaji Arisekola Alao, Chief Akanni Aluko dominated the social scene like the roaring lions dominated the jungle in Ibadan during their days.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "32-Year-Old Ogundoyin Emerges Speaker Of Oyo Assembly | Channels Television". www-channelstv-com.cdn.ampproject.org. Retrieved 10 June 2019. 
  2. 2.0 2.1 "31-year-old Ogundoyin emerges Oyo speaker". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 10 June 2019. 
  3. "PDP defeats APC in Oyo by-election". www-premiumtimesng-com.cdn.ampproject.org. Retrieved 10 June 2019. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  4. "PDP wins Ibarapa East State Constituency by-election". www.pulse.ng (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2 June 2018. Retrieved 10 June 2019. 
  5. University, Malam Adamu Adamu Oyo state House of AssemblyCurrent Speaker Incumbent Assumed office 10 June, 2019Personal detailsBornFebruary 18 is 31Alma mater Graduate of Babcock. "Biography of Debo Ogundoyin". Latest Nigerian News Today (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 16 June 2019. Retrieved 15 June 2019. 
  6. "Behold, Adebo Ogundoyin, Nigeria’s Youngest Speaker – THISDAYLIVE". www.thisdaylive.com. Retrieved 2022-12-16. 

Àdàkọ:Nigeria-politician-stub