Adewale Ademoyega

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Adéwálé Adémóyèga jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ológun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Adewale Ademoyega (died February 21, 2007) was one of the five mutinous Nigerian Army Majors who led the 1966 coup [1]th


that ended the first democratic Nigerian government.

Ìgbé ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Adéwáléní ìlú Òde Rẹ́mọ tí ó wà ní Ìpínlẹ̀ Ògùn tí ó wà ní àpérò ìwọ̀ Oòrùn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Adewale was born in Ode Remo in present-day Ogun State in southwestern Nigeria. He earned a degree in history from the University of London. He was one of the first graduates that enrolled as an officer in the Nigerian Army along with Lieutenant Colonels Chukwuemeka Odumegwu-Ojukwu and Victor Banjo, and Majors Olufemi Olutoye, Emmanuel Ifeajuna, and Oluwole Rotimi in the 1966 Nigerian army. Adewal Ademoyega was the last graduate to be commissioned directly into the Nigerian Army Infantry.

Ipa tí ó kò nínú ogun Biafra[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní àsìkò ogun abẹ́lé Biafra, Adéwálé jagun lábẹ́ ọmọ ogun orí ilẹ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, èyí tí ó jẹ́ apá kan nínú ikọ̀ ọmọ ogun tí adarí ogun Lieutenant Colonel Bajo kò sòdí. During the Biafran civil war, Adewale fought in the "Nigerian Liberation Army", a part of the Biafran army led by Lieutenant Colonel Banjo.

Major Ademoyega was released from detention by Biafran Head of State Colonel Chukwuemeka Odumegwu-Ojukwu, on August 13, 1966. He then formed the Biafran 19th Battalion and subsequently took over for Major Emmanuel Ifeajuna, who also helped with the 1966 coup as the chief of staff of the Liberation Army. Unfortunately for Major Ademoyega, His excellency Ojukwu received some intelligence that some officer would overthrow him. Major Ademoyega was detained along with several officers and comrades. Several of these officers would later be shot by Biafran forces. Maybe Ademoyega was spared however as he truly had nothing to o with this. He was detained for the remainder of the civil war.

Ademoyega was briefly 'freed' after the war. However, Federal forces put him right back in detention for his participation as part as the Liberation Army.

He was finally released along with twenty others during the 1974 Independence Day amnesty.

Ìdí tí a fi jà[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Major Adewale Ademoyega's book about the military coup d'état is regarded as one of the most authoritative regarding the first Nigerian coup.[2][3]

Ikú rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Adewale Ademoyega died on February 21, 2007 after being ill for sometime.[4]

Itọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Ademoyega: Leader of first coup". Vanguard News. 2018-08-11. Retrieved 2021-09-30. 
  2. Why We Struck Adewale Ademoyega Published in 1981, Evans Brothers (Ibadan, Nigeria)
  3. My command;An account of the Nigerian Civil War 1967-1970 Heinemann 1980
  4. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2016-06-04. Retrieved 2021-09-30. 


Àdàkọ:Africa-mil-bio-stub