Afẹ Babalọla
| Afe Babalola CON Order of the Federal Republic | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 30 Oṣù Kẹ̀wá 1929 Ado Ekiti, Southern Region, British Nigeria (now in Ekiti State, Nigeria) |
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigeria |
| Iṣẹ́ |
|
| Ìgbà iṣẹ́ | 1963–Present |
| Àwọn olùbátan | Bolanle Austen-Peters (daughter) |
| Awards |
|
| Website | afebabalola.com |
Afẹ Babalọla CON OFR SAN (Wọ́n bí i ní ọjọ́ ọgbọ̀n, oṣù kẹwà, ọdún 1929) jẹ́ agbẹjọ́rò ilẹ̀ [Nàìjíríà] àti Olùdásílẹ̀ ilé ìwé gíga ti Afẹ Babalọla[1][2][3].
Ìgbésí ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Afẹ́ Babalọlá ni à bí sí ìpínlẹ̀ Èkìtì ní gúúsù ìwọ oòrùn ilẹ̀ Naijiria. Arákùnrin náa lọ sí ilé ìwé akọbẹẹrẹ Emmanuel ní Ado-Ekiti[4]. Lẹ́yìn náà ló gba ìwé ẹ̀rí ilé ìwé Cambridge ní ibi tó ti kàwé ní alábàágbépọ̀ Wolsey, Oxford. Lẹ́yìn náà ló gba ìwé ẹ̀rí ti A'level kòtò dipé ó lọ sí ilé ìwé london níbi tó ti gboyẹ̀ lórí imọ ọ̀rọ̀ aje[5][6][7].
Arákùnrin náà ṣíṣe fún ìgbà díẹ̀ ni ile ìwé ifowopamọ àpapọ̀ ilẹ̀ Nàìjíríà kò tó di pé ó lọ sí ilé ìwé gíga London láti gboyè ni imọ òfin[8]. Ní ọdún 1963, wọn pé sì bar tí England, ọdún náà ló di ọ̀kan lára àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Lincoln Inn ní ìlú London.
Babalọla fẹ́ arábìnrin Modupẹ Mercy Babalọla tí wọ́n sì bímọ mẹ́sàn án lára wọn ni Bolanle Austen-Peters[9].
Isẹ́ Afẹ Babalọla gẹ́gẹ́ bí Amòfin
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Afẹ Babalọla bẹ̀rẹ̀ ìṣẹ rẹ ni ìlú Ibadan, èyí jẹ olú ìlú ipinlẹ Ọyọ, ìwọ oorun ilẹ̀ Nàìjíríà gẹ́gẹ́bí oludajọ ẹni tí a fẹ́ sunkan ni ilé iṣẹ́ Olú Ayọọla àti Co[10]. Lẹ́yìn ọdún méjì nínú iṣẹ́ adájọ́ ló dá ilé ìṣẹ idajọ tírẹ̀ sílẹ̀ Afẹ Babalọla Àti Co[11]. Ní ọdún 1987, arákùnrin náà di Alagba wí àgbà tí ilẹ Naijiria (SAN) , èyí jẹ ìṣẹ idajọ tó ga julọ[12].
Ní ọdún 2009, arákùnrin náà dá ilé ìwé gíga Afẹ Babalọla sílè ni ọ̀nà láti gbé ètò ẹ̀kọ́ lárugẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ní ọdún 2013, ilé ìwé náà jẹ́ ti aládàáni tó dára jù ní ipò ẹlẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà[13].
Ní ọdún 2002, Afẹ Babalọla darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ ìdásílẹ̀ àwọn olùdájọ́ orílè-èdè Nàìjíríà tó ṣì jẹ́ Ààrẹ fún ìdásílẹ̀ náà láti ọdún 2017 di October, 2021. Arákùnrin náà ṣíṣe takuntakun nígbà ìdarí rẹ ni ìdásílẹ̀ náà to jẹ pé lẹ́yìn tó fẹ̀yìntì ó jẹ Alátìlẹyìn NICArb àti ADR[14].
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Afe Babalola biography, net worth, age, family, contact & picture". Nigeria Business Directory - Find Companies, People & Places in Nigeria. 1929-10-30. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ Jacobs, Juwon (2015-07-13). "That Afe Babalola University May Truly Excel, Articles". thisdaylive.com. Archived from the original on 2015-07-13. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ "Aare Afe Babalola reacts to Omirin, APC lawmakers threat to shun peace meeting". Daily Post Nigeria. 2015-04-30. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ Ifeoma, Peters (2017-10-02). "Legal Luminary Profile: Aare Emmanuel Afe Babalola, SAN, CON, OFR -". - Blazing The Trails, Providing World Class Legal Services. Archived from the original on 2020-10-26. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ "A living legend: Afe Babalola". The Nation Newspaper. 2017-10-28. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ "I want to live beyond 114 years – Afe Babalola". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. 2011-02-23. Archived from the original on 2013-11-28. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ "Between Obafemi Awolowo and Afe Babalola - The Nation". The Nation. 2015-05-23. Archived from the original on 2015-07-07. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ Olatunji, Daud (2011-02-23). "At 80, Babalola teaches law at ABUAD". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 2015-02-18. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ "Yeye Aare Modupe Babalola,FSM,FNIMN". Afe Babalola University. 2017-03-03. Archived from the original on 2023-10-07. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ Bankole, Idowu (2022-05-20). "[Vanguard Awards] Afe Babalola: A lifetime of achievements". Vanguard News. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ Nigeria, Guardian (2015-03-11). "Lessons Learnt From Celebrating Aare Afe Babalola". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Archived from the original on 2016-05-13. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ "Babalola bags University of London LLD". sunnewsonline.com. 2015-02-22. Archived from the original on 2015-08-01. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ "Former minister, others applaud ABUAD’s law programme". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. 2011-02-23. Archived from the original on 2015-02-19. Retrieved 2023-10-04.
- ↑ Nigeria, Guardian (2021-10-12). "NICArb elects Ajogwu as president". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Archived from the original on 2023-04-30. Retrieved 2023-10-04.