Ajé

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Igba aje

Ajé jẹ́ òrìṣà tí Yorùbá gbàgbọ́ pé ó ṣẹ̀dá owó. Ajé jẹ́ orúkọ mìíràn tí Yorùbá máa ń pe owó. Láwùjọ Yorùbá, wọn a máa pe "owó" ní "ajé". Owó ẸyọÀrokò tí ó dúró gẹ́gẹ́ bí "Owó" tàbí "Ajé" láwùjọ Yorùbá. [1] [2]. Nílẹ̀ Yorùbá, wọ́n máa ń bọ Ajé gẹ́gẹ́ bí òrìṣà àkúnlẹ̀bọ. [3]

Oríkì Ajé[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ajé Káàárọ̀
Ajé olókun
Ajé Ògúgúlúṣọ̀, 
Ajé onísọ̀ ibòji
Asèwe dàgbà 
Asàgbà dèwe
Ẹni tí ẹrú àti ọmọ ń fi ojojúmọ́ wá kiri
Ìwọ ni àbámọ̀ tí ó borí ayé 
Ajé, Ìwọ làjíkí
Ajé, Ìwọ làjígẹ̀
Ajé, Ìwọ làjípè
Eni amúṣokun
Eni amúsedè
Iwo lani ra opolo aran aso oba ti kona yanranyanran
Aje agba orisha je ki ni lowo maje ki ni e lorun
Aje fi Ile MI se ibugbe, fi odede 
MI se ibura, aje o jire loni óò. [1]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 Salami, Segilola (2018-04-26). "Oriki Aje: Praise Poetry for the Goddess of Wealth and Prosperity". Segilola Salami. Retrieved 2019-12-31. 
  2. Webmaster (2019-12-31). "Understanding Wealth Creation (Aje) Through the Concept of Yoruba Traditional Religion". NICO. Archived from the original on 2019-12-31. Retrieved 2019-12-31. 
  3. "AJE: Yoruba deity of wealth". The Sun Nigeria. 2018-03-07. Retrieved 2019-12-31.