Alimotu Pelewura

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Alimotu Pelewura
Political partyNigerian National Democratic Party

Oloye Alimotu Pelewura, (1865–1951) jẹ onísòwò Naijiria kàn tó jẹ adarí ẹgbẹ awon obinrin ti oja Eko, egbé agbawi obìnrin tí o jẹ onísòwò ní Eko. O tún jẹ ẹlẹgbẹ òṣèlú pàtàkì ti Herbert Macaulay . [1]

Ìgbésí ayé ìbẹ̀rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìlú Eko ní wón tí bí Pelewura si idile nla kan. Ó jẹ́ àgbà ti àwọn ọmọ méjì tí ìyá rẹ̀ bí. Ìya rẹ jẹ oníṣòwò ẹja àti Pelewura tún yan ìṣòwò ẹja gégébí iṣẹ. Ní ọdún 1900, o tí di aṣáájú àwọn obìnrin àti onísòwò ọjà pàtàkì àti ní ọdún 1910, Oba Eshugbayi Eleko fún ní oye olori . Ní awọn ọdun 1920, o jẹ aṣaaju ọjà ẹran Ereko pẹlu atilẹyin Herbert Macaulay, o dìde láti di olórí ẹgbẹ tuntun tí àwọn obìnrin tí Ọjà eko. Ó jẹ́ ọmọ ẹ̀yà Awori ti Yorùbá [2]

Awọn itọkasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Johnson 1978, pp. 45.
  2. Historical Society of Nigeria. 1965. Tarikh. [Ikeja, Lagos State, Nigeria]: Published for the Historical Society of Nigeria by Longmans of Nigeria Ltd. P. 2