Ayo Adesanya
| Ayo Adesanya | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 11 Oṣù Kẹjọ 1969 Ogun State, Nigeria |
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Iṣẹ́ |
|
| Ìgbà iṣẹ́ | 1986–present |
Ayọ́ Adésànyà (tí wọ́n bí ní Ọjọ́ kọkànlá oṣù kẹjọ ọdún 1969) jẹ́ àgbà òṣèrébìnrin, olùdarí àti olóòtú sinimá àgbéléwò lédè Yorùbá àti Gẹ̀ẹ́sì.[1][2] [3] Ó tún jẹ́ adarí àti olóòtú eré.[4][5] Ayo Adesanya máa ń ṣàfihàn nínuụ eré Yorùbá àti ti Gẹ̀ẹ́sì.
Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ijagu, ní ìlú Ijebu, ní Ipinle Ogun ni Ayo Adesanya ti wá, ìyẹn ní apá Gúúsù ti apá ìwọ̀-oòrùn orílẹ̀-èdè Naijiria. Ilé-ìwè St. Anne's ní ìlú Ibadan ni ó ti kàwé, fún ti alákọ̀ọ́bèrẹ̀ àti ti girama. Lẹ́yìn náà, ó lọ University of Ibadan láti lọ kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú Mass Communication.[6]
Iṣẹ́ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ayo Adesanya bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ ní ọdún 1986 lẹ́yìn tí ó sin orílẹ̀-èdè rẹ̀ tán, ìyẹn NYSC. Ní ọdún 1996, ó darapọ̀ mọ́ àwọn tí ń ṣe eré àgbéléwò ti orílẹ̀-èdè Naijiria. Fíìmù Tunji Bamishigbin tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ Palace ní wọ́n ti kọ́kọ́ se àfihàn rẹ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́.[7] Ó padà darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ àwọn tí ń ṣe fíìmù Yorùbá. Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ sí ní darí eré, tó sì ń gbé eré jáde. Ó ti gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré jáde, ó sì ti darí eré púpọ̀.[8] Ayo Adesanya tún máa ń ṣe fíìmù Yorùbá àti ti Gẹ̀ẹ́sì.[9]
Ayé rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Ayo Adesanya fìgbà kan jẹ́ ìyàwó Goriola Hassan, àmọ́ wọ́n ò fẹ́ ara wọn mọ́ báyìí. Ó bí ọmọkùnrin kan.[10]
Díẹ̀ lára àwọn eré àgbéléwò tíó tí kópa
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Living in Bondage (1992) as Favour
- Living in Bondage 2 (1993) as Favour
- Silent Night (1996) as Extra
- Out of Bounds (1997) as Adaora
- Most Wanted (1998) as Backside
- Tokunboh (1999) as Mudy
- Remember Your Mother (2000) as Efe
- Time (2000) as Aghata
- Fire Dancer (2001) as Selena
- Contractors (2003)
- Dark Secret (2004)
- Crazy Passion (2005) as Pamela
- Tears in My Heart 2 (2006) as Dr. Rita
- Scarlet (2014)
- The Good Wife (2015) as Priscillia
- Dark Spotlight (2016) as Mrs. Adam
- Omugwo (2017) as Candance
- Finding Happiness (2018) as Kate
- Mokalik (2019) as Ireti
- Family Guest (2020) as Theresa
- A Christmas Gift (2020)
- Suga Suga (2021) as Ireti
- Just Us (2022) as Beatrice
- Love Unbroken (2023) as Diana
- Barrage (2023) as Mrs. Bamidele
- The Colour of Lies (2023)
- The Farewell Plan (2024)
- Trenches Kid (2024) as Williams' Mum
- Faithful Love (2024) as Diana
- Greener Pastures (2024) as Mama Efosa
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Ayo Adesanya Finds Love Again". THISDAY LIVE. Archived from the original on 24 February 2015. Retrieved 24 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Ruth Olurounbi. "I would have married Ayo Adesanya - Pasuma". tribune.com.ng. Archived from the original on 24 February 2015. Retrieved 24 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Chioma, Ella (2021-04-04). "Actress Ayo Adesanya opens up on dating men in Yoruba movie industry". Kemi Filani News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-03-15.
- ↑ "Ayo Adesanya Finds Love Again". THISDAY LIVE. Archived from the original on 24 February 2015. Retrieved 24 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Ruth Olurounbi. "I would have married Ayo Adesanya - Pasuma". tribune.com.ng. Archived from the original on 24 February 2015. Retrieved 24 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "My eyes are blessings from God - Ayo Adesanya - Vanguard News". Vanguard News. Retrieved 24 February 2015.
- ↑ "I was never married to Goriola Hassan –Ayo Adesanya". The Punch. Archived from the original on 28 February 2015. Retrieved 24 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "Simplicity gives my life balance –Ayo Adesanya". The Punch. Archived from the original on 28 February 2015. Retrieved 24 February 2015. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ "I can never go back to my ex-husband –Ayo Adesanya, actress". The Sun (Nigeria). 10 June 2016. Retrieved 15 September 2016.
- ↑ Latestnigeriannews. "My ex-husband and I were never legally married Ayo Adesanya". Latest Nigerian News. Retrieved 24 February 2015.