Command and Staff College, Jaji

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Armed Forces Command and Staff College
Established1976
TypeStaff college
Parent institutionNational Defence College, Nigeria
Religious affiliationNigerian Armed Forces
CommandantAir vice-marshal Ebenezer Olayinka Alade
LocationIgabi, Kaduna StateJaji, Naijiria, Naijiria
CampusRural
Websiteafcsc.mil.ng

Armed Forces Command and Staff College, Jaji jẹ́ ilé-ìgbẹ̀kọ́ fún àwọn Nigerian Armed Forces pẹ̀lú àwọn ajagun orí òfurufú àti abẹ́-omi. Ó súnmọ́ ìlú Jaji, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní apá àríwá ilẹ̀ Kàdúná lábẹ́ ìjọba ìpínlẹ Igabi. Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, Air Vice Marshal Ebenezer Olayinka Alade ló ń darí ilé-ìwé náà.[1]

Ìtàn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

The Armed Forces Command and Staff College jẹ́ ilé-ìwé tí wọ́n dá sílẹ̀ ní oṣù karùn-ún, ọdún 1976, pẹ̀lú iṣẹ́ akọ́ni àgbà méjì. Ní oṣù kẹrin, ọdún 1978, ilé-ìwé náà gbòrò si nígbà tí wọ́n dá ẹ̀ka àwọn ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ kalẹ̀.[1] Oṣù kẹjọ, ọdún 1981 ni wọ́n fi ẹ̀kọ́ àwọn ológun ti abẹ́-omi kún ètò-ẹ̀kọ́ ilé-ìwé náà.[2]

Ètò-ẹ̀kọ́ àwọn adarí àgbà dálé lórí àwọn ẹ̀kọ́ tí wọ́n rí nínú ètò-ẹ̀kọ́ àwọn Britain, ti British Army Staff College, ní Camberley.[2]

Ní oṣù kẹjọ, ọdún 2005, adarí àwọn ọmọ-ológun ti òkè-òkun, Adams Ingram yọjú sí Jaji, ó sì gbé owó tó tó bíi 200,000 pounds kalẹ̀ láti fi ran ilé-ìwé náà lọ́wọh.[3] Ní oṣù kọkànlá ọdún 2006, ọmọọba ti ìlú Wales láti ìlú United Kingdom wá sí Nàìjíríà láti wá ṣe àbẹ̀wò sí àwọn ológun tó wà ní Jaji.[4]

Àwọn òṣìṣẹ́ tó lààmìlaka[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn tó ti ṣetán tó ti lààmìlaka[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "Armed Forces Command and Staff College (AFCSC) Jaji". Armed Forces Command and Staff College (AFCSC) Jaji. Retrieved 2021-05-02. 
  2. 2.0 2.1 "Nigeria - Training". Federal Research Division of the Library of Congress. Retrieved 2009-11-18. 
  3. "PRESS NOTICE: UK trains an extra 17,000 Nigerian peacekeepers". UK Ministry of Defence. 20 September 2005. Archived from the original on 24 March 2010. Retrieved 2009-11-18. 
  4. "The Prince of Wales visits Nigeria". Prince of Wales. 29 November 2006. Retrieved 2009-11-18.