Jump to content

Femi Gbajabiamila

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Rt. Hon.

Femi Abdulhakim Gbajabiamila
Femi Gbajabiamila
Speaker of the House of Representatives of Nigeria
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
June 2019
AsíwájúYakubu Dogara
House Leader of the House of Representatives of Nigeria
In office
June 2015  June 2019
AsíwájúOgor Okuweh
Minority Leader of the House of Representatives of Nigeria
In office
June 2011  June 2015
Arọ́pòOgor Okuweh
Minority Leader of the House of Representatives of Nigeria
In office
June 2007  June 2011
AsíwájúAhmed Salik
Member of the House of Representatives of Nigeria
In office
2003–2007
Asíwájúyakubu Dogara
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí25 Oṣù Kẹfà 1962 (1962-06-25) (ọmọ ọdún 63)
Lagos State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress (APC)
ResidenceLagos
Alma materUniversity of Lagos
OccupationLegislature
Websitehttp://femigbajabiamila.com

Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n oṣù kẹfà ọdún 1962 (June 25, 1962) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèlú, Agbẹjọ́rò àti Agbẹnusọ Ilé-Ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú, All Progressives Congress tí ó ń ṣojú ìjọba ìbílẹ̀ Sùúrùlérè ni ìpínlẹ̀ Èkó láti ọdun 2019[1] [2] [3] [4]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ àti ẹ̀kọ́ rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Olufemi "Femi" Hakeem Gbajabiamila ní 25 June 1962 sí ìdílé Mr àti Mrs Lateef Gbajabiamila àti Olufunke Gbajabiamila ni Ìpínlè Èkó, Nàìjíríà. Ó lọ ilé ìwé àkọ́bẹ̀rẹ̀ ti Mainland fún àkọ́bẹ̀rẹ̀ àti Igbobi College[5] ní ọdún 1973, níbi tí ó ti parí ẹ̀kọ́ girama rẹ̀. Ó tún padà lọ King's William's College ni Isle Of Man, orílè-èdè United Kingdom fún ìwé-ẹ̀rí A-Level rẹ̀.[6] Wọ́n gbà sí Yunifásítì Ìlú Èkó, Nàìjíríà.[7] níbí tí ó ti gba àmì-ẹ̀yẹ nínú ìmò òfin(LL.B) pẹ̀lú ẹ̀yẹ ní ọdún 1983, a sì pé é láti wá ṣiṣẹ́ òfin(call to bar) ní ọdún 1984.

Ó kọ́kọ́ ṣiṣẹ́ ni ilé-ìṣẹ́ agbẹjọ́rò Bentley Edu &Co., ní ìpínlè Eko, kí ó tó dá ilé-iṣẹ́ agbẹjọ́rò kan, Femi Gbaja & Co. kalẹ̀.

Ipa rẹ̀ nínú òṣèlú

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A yan Gbajabiamila sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní ọdún 2003, ó sì ń ṣe aṣojú Surulere I ní ìpínlẹ̀ Èkó.

Gbajabiamila máa ń sọ̀rọ̀ lòdì sí bí àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ṣe máa ń yí láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan sí òmíràn.


Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "THISDAYonline". BNW News. Archived from the original on 2020-01-13. Retrieved 2020-01-13.
  2. Assembly, Nigerian National (1962-06-25). "Federal Republic of Nigeria". National Assembly. Retrieved 2020-01-13.
  3. "When encomiums poured in torrents for Femi Gbajabiamila in Lagos". Premium Times Nigeria. 2012-06-27. Retrieved 2020-01-13.
  4. "Ahmed Lawan, Femi Gbajabiamila go lead Nigeria 9th National Assembly". BBC News Pidgin (in Kúẹ́ńjùà). 2019-06-11. Retrieved 2020-01-13.
  5. "What Osinbajo, Gbajabiamila have in common". The Nation Newspaper (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-02-05. Retrieved 2022-02-28.
  6. Ibiam, Agha (2004-02-07). "Gbaja-Biamila: Shocked Beyond Belief...". Thisday (BNW). Archived from the original on 2011-07-07. https://web.archive.org/web/20110707233300/http://news.biafranigeriaworld.com/archive/2004/feb/07/0043.html. Retrieved 2007-11-11.
  7. "Hon. Femi Gbaja Biamila". National Assembly website. National Assembly of Nigeria. Archived from the original on 2016-03-03. Retrieved 2007-10-23. Unknown parameter |url-status= ignored (help)