Jump to content

Femi Otedola

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Femi Otedola
Ọjọ́ìbí4 Oṣù Kọkànlá 1962 (1962-11-04) (ọmọ ọdún 63)
Ibadan, Oyo State, Nigeria
Ẹ̀kọ́Olivet Baptist High School
Obafemi Awolowo University
Iṣẹ́Businessman
Olólùfẹ́Nana Otedola
Àwọn ọmọ4, including Temiloluwa Elizabeth Otedola
Parent(s)Sir Michael Otedola

A bí Femi Otedola ní ọjọ kẹẹ̀rin, oṣù kọkànlá ọdún 1962, ó jẹ́ onísòwò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, onkowe, onínúure, àti alága tẹ́lè fún Forte Oil PLC. Lówọ́lówó, Ó jé álágá Geregu Power PLC. O je okan ninu awon o je okan ninu awon olowo agba to ni okiki ni orile ede Naijiria ati lorile Africa. Femi Otedola je aare ile eko giga ti oun je Augustine University ni Ilara-Epe ni Ipinle Eko.

Ìgbésí ayé ìbẹ̀rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Otedola ní ìlú Ìbàdàn, olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, gúúsù ìwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, nínú ìdílé olóògbé Sir Michael Otedola, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó láti 1992 sí 1993.[1] Arakunrin Femi Otedola se igbeyawo pelu Nana Otedola, Ile Iwe Obafemi Awolowo University ni o ti jade leyin eyi to bere si ni mojuto ise ite iwe baba re, to si je ipinle irin ajo re gege bi ogbontarigi oni ise aje..

  1. "Ex-Lagos gov, Sir Michael Otedola, dies at 87". Vanguard News. 2014-05-05. Retrieved 2022-02-06.