Godwin Emefiele
Godwin Emefiele | |
---|---|
Godwin Emefiele (lọ́wọ́ ọ̀tún) pàdẹ́ Jacob J. Lew àti Sarah Bloom Raskin | |
Gómìnà banki àpapò Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 3 June 2014 | |
Asíwájú | Sarah Alade (Acting)[1] |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | 4 Oṣù Kẹjọ 1961 Agbor, Delta State, Nigeria. |
Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
(Àwọn) olólùfẹ́ | Margaret Emefiele |
Àwọn ọmọ | 2 |
Education | Master of Arts degree in Finance |
Alma mater | Yunifásitì ti Nàìjíríà |
Godwin Emefiele (tí a bí ní ọjọ́ kẹrin oṣù kẹjọ ọdun 1961) jẹ́ olóṣèlú ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[2][3] àti Gómìnà-àná Ilé ìfowó pamọ́ àgbà Nàìjíríà láti ọjọ́ kẹrin oṣù kẹfà ọdun 2014 títí di ọjọ́ kẹsàn-án oṣù kẹfà ọdún 2023 tí Ààrẹ Bọlá Ahmed Tinubu pàṣẹ láti dá a dúró lẹ́nu iṣẹ́ nítorí ẹ̀sùn àwọn ìwà àjẹbánu kan.[4] [5]
Ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Emefiele lọ Ansar Udin Primary School àti Maryland Comprehensive Secondary ní ìpínlẹ̀ Èkó, kí ó tó lọ Yunifásítì ilẹ̀ Nàìjíríà (UNN) láti tẹ ẹ̀kọ́ rẹ̀ síwájú. Ó gba àmì-èye nínú ìmò Banking and Finance, Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn tí ó yege jù láàrin àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìyókù rẹ̀. Léyìn ìgbà tí Emefiele sin ilẹ̀ baba rẹ̀, ó padà sí Yunifásitì ti Nàìjíríà láti gba àmì-ẹyẹ Masters Degree nínú ìmò Finance ní ọdun 1986. Ni Oṣu Kẹfa Ọjọ 10, Ọdun 2023, Ẹka Awọn Iṣẹ ti Ipinle ṣe idaniloju imuni Emefiele nipasẹ oju-iwe Twitter osise rẹ. Iroyin fi to wa leti wipe won gbe e wa fun iforowero gege bi ara iwadii ninu ofiisi re.[1]. Ni Oṣu Kini ọdun 2024, ile-ẹjọ kan ni Abuja paṣẹ fun ijọba apapọ orilẹ-ede Naijiria lati san 100 milionu naira (€100,000) ni bibajẹ fun Godwin Emefiele fun atimọle arufin.[2].
Àwọn Ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "Central Bank of Nigeria:: Board of Directors".
- ↑ https://guardian.ng/news/cbn-governor-emefiele-joins-presidential-race-obtains-apc-form/
- ↑ "APC ward chairman confirms Emefiele's membership, says CBN gov registered Feb 2021". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-05-09. Retrieved 2023-02-24.
- ↑ "Profile of Godwin Emefiele, new CBN GOV". Vanguard Nigeria. February 20, 2014.
- ↑ Bankole, Idowu (2023-06-10). "Tinubu suspends CBN Gov, Emefiele". Vanguard News. Retrieved 2023-06-10.