Bola Tinubu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Bola Tinubu
Asiwaju Bola Ahmed Tinubu (5980497975).jpg
12th Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó
In office
May 29, 1999 – May 29, 2007
AsíwájúBuba Marwa (military admin.)
Arọ́pòBabatunde Fashola
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíOṣù Kẹta 29, 1952 (1952-03-29) (ọmọ ọdún 71)
Lagos State, Nigeria
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress
OccupationPolitician

Bọ́lá Ahmed Tinúbú (ọjọ́ ìbí Ọjọ́ kàndínlọ́gbọ̀n oṣù Kẹ́ta, ọdun 1952) jẹ́ olóṣèlú ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, òun ni ó jáwé olúborí nínú ìdìbò ààrẹ ọdun 2023, òun sì ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó láàrin ọdún 29 May odun 1999 títí di ọdún 29 May, 2007.[1] Àwọn ará ìlú ti kọ́kọ́ dìbò yàn Bola Ahmed Tinubu láti di Sẹ́nétọ̀ ní ọdún 1992, àmọ́ wọ́n fagilé ìbò náà ní ọdún (12 June, 1993)[2]

Kíkéde ète láti dupò ààre[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní ọjọ́ kọkànlá, oṣù kíní, ọdún 2022(January 11, 2022), Bola Ahmed kéde ète rẹ̀ láti dupò ààrẹ Nàìjíríà ní odún 2023 lábé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress(APC).[3] Ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹfà ọdún 2022, Tinubu jáwé olúborí nínú ìdìbò-abẹ́lé ààrẹ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress(APC) pẹ̀lú àmì ayò 1271, láti borí Igbákejì Ààrẹ Yẹmí Ọ̀ṣínbàjò àti Rotimi Amaechi tí ó gba 235(Osinbajo) àti 316(Rotimi).[4][5]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Bola Ahmed Tinubu - Profile". Africa Confidential. 2019-10-07. Retrieved 2019-10-07. 
  2. "'Tinubu Died At A Time Nigeria, Lagos Needed His Wealth Of Experience', Sanwo-Olu Says Of Ex-Lagos Head Of Service". Sahara Reporters. 2019-09-06. Retrieved 2019-10-07. 
  3. Daka, Terhemba; (Abuja), Adamu Abuh; Harcourt), Ann Godwin (Port; (Yenagoa), Julius Osahon; (Ibadan), Rotimi Agboluaje (2022-01-11). "Tinubu confirms presidential ambition: I’m a kingmaker, I want to be king - Nigeria and World News". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Retrieved 2022-04-27. 
  4. AFP, Le Monde avec (2022-06-08). "Présidentielle au Nigeria : l’ancien gouverneur de Lagos, Bola Tinubu, remporte la primaire du parti au pouvoir". Le Monde.fr (in Èdè Faransé). Retrieved 2023-04-01. 
  5. Akoni, Olasunkanmi (June 11, 2022). "APC: Why Tinubu is yet to visit pan Yoruba, Igbo groups - Aide". Vanguard News. Retrieved June 12, 2022.