Babátúndé Fáṣọlá
(Àtúnjúwe láti Babatunde Fashola)
His Excellency Babátúndé Rájí Fáṣọlá SAN | |
---|---|
![]() | |
Minister of Works and Housing | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 11 November 2015 | |
Ààrẹ | Muhammadu Buhari |
13th Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó | |
In office May 29, 2007 – May 29,2015 | |
Asíwájú | Bola Tinubu |
Arọ́pò | Akinwunmi Ambode |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | Oṣù Kẹfà 28, 1963[1] Lagos State, Nigeria |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressive Congress |
(Àwọn) olólùfẹ́ | Abimbola Emmanuela Fashola |
Occupation | lawyer, Politician |
Babátúndé Rájí Fáṣọlá (ọjọ́-ìbí 28 June, 1963) jẹ́ Agbẹjọ́rò ati onísèlú órílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[2] Ó ti fìgbà kan jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó fún sáà méjì Láti ọdún 2007 sí ọdún 2015 lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́-òṣèlú All Progressives Congress. Olóyè Bola Tinubu ni ó jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó ṣáájú rẹ̀.[3] Lodun 2015, Ààrẹ Muhammadu Buhari yàn-án gẹ́gẹ́ bí Mínísítà fún ètò iná-mọ̀nàmọ́ná, ilé gbèé, àti iṣẹ́. Ààrẹ tún tún-un yàn lọ́dún 2019 sí ipò yí kan náà yànọ̀ sí ipò Mínísítà fún Agbára àti ìná mọ̀nàmọ́ná.[4]
![]() |
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |
wo eleyi na[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Àwọn Ìtọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "HIS EXCELLENCY, BABATUNDE RAJI FASHOLA (SAN), GOVERNOR OF LAGOS STATE, NIGERIA". Commonwealth Business Council. Retrieved 2010-02-14.
- ↑ "Governor Babatunde Raji Fashola - Profile". Africa Confidential. 2019-10-03. Retrieved 2019-10-03.
- ↑ "Babatunde Fashola". Wikipedia. 2007-10-24. Retrieved 2019-10-03.
- ↑ Toromade, Samson (2019-08-21). "Fashola loses Power ministry, retains Works and Housing". Google. Retrieved 2019-10-03.
Ìkìlọ̀: Bọ́tìnì ìtò àkọ́kọ́ṣe "Fáṣọlá, Babátúndé" dípò Bọ́tìnì ìtò àkọ́kọ́ṣe "Fashola, Babatunde" tẹ́lẹ̀.