Jemima Osunde

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Jemima Osunde
Osunde appearing on an episode of NdaniTV's Real Talk
Ọjọ́ìbíApril 30 1996 (age 24)
Lagos, Lagos State, Nigeria
Iléẹ̀kọ́ gígaUniversity of Lagos
Iṣẹ́
Gbajúmọ̀ fúnShuga
WebsiteOfficial website

Jemima Osunde tí wọ́n bí ní ọgbọ̀njọ́ oṣù Kẹrin ọdún 1996. [1] jẹ́ òṣèré orí-ìtàgé , model àti olóòtú ètò lórí ẹ̀rọ amóhù-máwòrán Ọmo orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[2] Ó di ìlú-mòọ́ká lẹ́yìn tí í ó kópa gẹ́gẹ́ bí ẹ̀dá-ìtàn "Jemima" nínú eré àtìgbà-dégbà onípele ti Shuga.[3]Wọ́n yan Osunde fún amì-ẹ̀yẹ ti Best Actress in a Leading Role àyẹyẹ 15th Africa Movie Academy Awards ẹlẹ́kẹẹ̀ẹ́dógún irú rẹ̀ tí yóò wáyé fún ipa rẹ̀ tí ó kó nínú eré The Delivery Boy (2018).[4]

Ìbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Osunde sí ìlú Edo, ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa physiotherapy ní ilé-ẹ̀kọ́ Yunifásitì Ìpínlẹ̀ Èkó.[5][6][7]Ó kópa nínú eré Jungle Jewel lẹ́yìn tí àbúrò bàbá rẹ̀ gbàá níyànjú láti máa lọ ṣeré ìtàgé.

Ó kópa bí ẹ̀dá-ìtàn "Laila" nínú eré àtìgbà-dégbà onípele ti MTV Shuga.Ó pa ìkópa tì nínú eré yí nígbà tí wọ́n gbé eré náà lọ sí orílẹ̀-èdè South Africa, àmọ́ ó tún bá wọn kópa padà nígba tí eré náà padà sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. [8] Ní ọdún 2018, ó kópa nínú eré Rumour Has it pẹ̀lú òṣèré mìíràn bíi: Linda Ejiofor lórí NdaniTV's .[9][10]

Osunde tún báwọn kópa nínú ìpele keje lórí MTV Shuga lásìkò ìsémólé COVID-9 .[11][12].

Ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní ọdún 2019, Osund jáde ẹ̀kọ́ nílé ẹ̀kọ́ Yunifásitì Èkó nínú ìmọ̀ physiotherapy.[13]

Àwọn àṣàyàn eré rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

playing MTV Shuga's Leila during lockdown in 2020

Àwọn eré amóhù-máwòrán[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Shuga
  • This Is It (2016–2017)
  • Rumour Has It (2018)

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Birthday Girl Jemima Osunde is Painting the Town Red from her Couch". BellaNaija. 30 April 2020. Retrieved 30 April 2020. 
  2. "Jemima Osunde biography, age and lifestyle" (in en). Uzomedia TV Youtube. https://www.youtube.com/watch?v=frDdos2Ic_s. 
  3. "I'm a no nonense person – Jemima Osunde". 
  4. Shaibu Husseini (28 September 2019). "AMAA 2019 nomination: Four ‘huge’ slots for Nollywood’s leading ladies". Guardian Life. Retrieved 30 April 2020. 
  5. "A Brief Spotlight On Genevieve Nnaji’s Amazing ‘Lookalike’, Jemima Osunde". 
  6. "Budding actress, Jemima Osunde up against Adesua Etomi?". 
  7. "Actress is what Nigeria needs at this time". 
  8. Obioha, Ikenna (7 Jan 2018). "How I got global fame – Jemima Osunde, actress". The Sun. http://sunnewsonline.com/how-i-got-global-fame-jemima-osunde-actress/. 
  9. NdaniTV (2018-03-14), Go Behind The Scenes of Rumour Has It Season 2, retrieved 2018-03-15 
  10. NdaniTV (2018-04-20), Rumour Has It S2E5: Janus, retrieved 2018-04-23 
  11. "MTV Shuga: Alone Together | Episode 7". YouTube MTV Shuga. 20 April 2020. Retrieved 29 April 2020.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  12. Akabogu, Njideka (2020-04-16). "MTV Shuga and ViacomCBS Africa Respond to COVID-19 with "Alone Together" Online Series". BHM (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-04-30. 
  13. Odion Okonofua (March 28, 2019). "Jemima Osunde graduates from medical school". Pulse Nigeria. Retrieved 25 January 2020. 

Àwọn Ìtàkùn ìjásóde[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]