Mohammed Mustapha Namadi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Mohammed Mustapha Namadi
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíOṣù Kẹta 25, 1959 (1959-03-25) (ọmọ ọdún 65)
Kano State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress (APC)
Alma materBayero University Kano, Florida State University
ProfessionMedical sociologist

Mohammed Mustapha Namadi jẹ́ ọmọ bíbí orílẹ́-èdè Nàìjíríà, wọ́n bí i ní ọjọ́ karùndínlọ́gbọ̀n, oṣù kẹta, ọdún 1959 (March 25, 1959) ní Ìpínlẹ̀ Kano. Ó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n (Professor) tí ó sì tún jẹ́ adarí àgbà ní agbo tí a ti ń kọ́ nípa ìmọ̀-ìjìnlẹ̀ àwùjọ (Dean Faculty of Social Sciences), ní yunifásítì ìjọba àpapọ̀ ti Kashere ní Ìpínlẹ̀ Gombe Nàìjíríà.[1][2] Ó ti fi ìgbà kan rí jẹ́ kọmísọ́nà fún ètò ẹ̀kọ́[3] àti Kọmísọ́nà fún ohun ọ̀gbìn àti àwọn àlùmọ́ọ́nì inú ilẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Kano, orílẹ́-èdè Nàìjíríà. Nínú oṣù karùn-ún ọdún 2021, Ààrẹ Muhammadu Buhari yàn án sí àjọ olùdarí ti Ilé-iṣẹ́ àwọn àgbàlagbà tí wọ́n jẹ́ ọmọ bíbí orílẹ́-èdè Nàìjíríà (Governing Body of the National Senior Citizens Centre).

íwọ́n jẹ́ ọmọ tiílẹ́ilẹ-è(he Governing Body of the National Senior Citizens Centre).

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Department of Sociology". Federal University of Kashere. Retrieved 30 September 2023. 
  2. "Our Staff". Federal University of Kashere. Retrieved 30 September 2023. 
  3. "Kano Delegation Arrive Wisconsin". New Nigeria. New Nigerian. 2008-10-08. Archived from the original on 2011-07-13. Retrieved 2023-09-30.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)