Muhammad Mustapha Olaroungbe Akanbi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Mohammed Mustapha Olaroungbe Akanbi
Born24 January 1971
Died24 January 2022(2022-01-24) (ọmọ ọdún 51)
Ilorin, Kwara State
NationalityNigeria

Muhammad Mustapha Olaroungbe Akanbi SAN (tí wọ́n bí ní 24 January 1971, tó sì ṣaláìsí ní 20 November 2022) jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ẹ̀kọ́ òfin ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, àti igbá kejì olùarí Kwara State University.[1][2] Ó fìgbà kan jẹ́ ọmọ-ẹgbẹ́ Senior Advocate of Nigeria àti Nigeria Bar Association.

Ìbẹ̀rèpẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Mustapha Akanbi ní ọdún 1971 ní Ile Magaji Kemberi, Awodi, Gambari Quarters, Ilorin East, ní Ìpínlẹ̀ Kwara ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sí ìdílé Mustapha Akanbi, tó jẹ́ òṣìṣẹ́ ìjọba.[3][4][5] Ó gba ìé-ẹ̀rí West African School Certificate láti Federal Government College Okigwe ní ọdún 1989. Ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ̀ òfin ní Obafemi Awolowo University ní ọdún 1993. Ó gboyè ẹ̀kọ́ ní Nigerian Law School ní ọdún 1995 wọ́n sì pè é sí iṣẹ́, sí ilé-ẹjọ́ ní ọdún kan náà.[4] Ní ọdún 1998, ó gboyè Masters degree nínú ìmọ̀ òfin ní University of Lagos, ní ọdún 1998 ó gboyè Ph.D ní University of London's King's College London, ní United Kingdom ní ọdún 2006.[4][6]

Iṣẹ́ tó yàn láàyò[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Iṣẹ́ ní ìlànà ẹ̀kọ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Mustapha Akanbi bẹ́rẹ́ iṣé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i olùkọ ní faculty of Law ní University of Ilorin, ó sì di ọ̀jọ̀gbọ́n ní ọdún 2012.[7][8] Akanbi fìgbà kan jẹ́ olórí ẹ̀ka Department of Business Law, àti Dean of faculty of Law ní University of Ilorin. Ó sì jẹ́ igbá kejì olùdarí Kwara State University, Malete, títí tí ó fi kú.[9][10]

Iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gé ní onímọ̀ òfin[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Mustapha Akanbi ṣiṣẹ́ fún orílẹ̀-èdè rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i legal assistant ní legal department ti Central Bank of Nigeria ní Èkó láti ọdún 1995 wọ ọdún 1996. Ní legal firms Gafar & Co, Ilorin àti Wole Bamgbala & Co, Lagos, Olawoyin àti Olawoyin, Lagos àti Ayodele, bákan náà ló ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i òṣìṣé kékeré láti March 1996 títí wọ 1998.[11]

Àwọn ẹgbẹ́ tó darapọ̀ mọ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó di ọmọ-ẹgbẹ́ Nigerian Bar Association ní ọdún 1995, àti ọmọ-ẹgbẹ́ Senior Advocate of Nigeria ní ọdún 2018.[4]

Àṣààyàn àwọn ìwé tó kọ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Corruption and the challenges of good governance in Nigeria;[12]
  • Rule of law in Nigeria;[13]
  • The Case For The Integration;[14]
  • Customary arbitration in Nigeria: a review of extant judicial parameters and the need for paradigm shift (2015);[15]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Odinkalu, Chidi. "Mustapha Muhammad Akanbi". The Cable. 
  2. TVCN (2022-11-20). "KWASU VC, Professor Akanbi, dies in Ilorin - Trending News" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-12-06. 
  3. Odinkalu, Chidi. "Mustapha Muhammad Akanbi". The Cable. 
  4. 4.0 4.1 4.2 4.3 Iwayemi, Zainab (2022-11-21). "Professor Muhammed Akanbi: The academic icon who bagged professorship at 40". Nairametrics (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-12-06. 
  5. ODINKALU, CHIDI (2022-11-27). "Tribute to Mohammed Mustapha Olaroungbe Akanbi, January 24, 1971–November 20, 2022". Peoples Gazette (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-12-06. 
  6. Odinkalu, Chidi Anselm. "Mohammed Mustapha Olaroungbe Akanbi (1971-2022)". Premium Times. Retrieved 2023-12-06. 
  7. Iwayemi, Zainab (2022-11-21). "Professor Muhammed Akanbi: The academic icon who bagged professorship at 40". Nairametrics (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-12-06. 
  8. Chioma, Unini (2022-11-20). "KWASU VC, Prof M.M. Akanbi (SAN), Is Dead". TheNigeriaLawyer (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-12-06. 
  9. Odinkalu, Chidi. "Mustapha Muhammad Akanbi". The Cable. 
  10. ODINKALU, CHIDI (2022-11-27). "Tribute to Mohammed Mustapha Olaroungbe Akanbi, January 24, 1971–November 20, 2022". Peoples Gazette (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-12-06. 
  11. "BREAKING: KWASU Vice Chancellor Prof Akanbi dies at 52". Intel Region (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-11-20. Retrieved 2023-12-06. 
  12. M. M., Akanbi (2004). "Corruption and the challenges of good governance in Nigeria". University of Lagos, Faculty of Social Sciences Journal 6. 
  13. Mustapha Akanbi, Mohammed; Taiwo Shehu, Ajepe (2012). handle=hein.journals/jawpglob3&section=2 "Rule of law in Nigeria". Journal of Poly and Globalization 3: 1. https://heinonline.org/hol-cgi-bin/get_pdf.cgi handle=hein.journals/jawpglob3&section=2. 
  14. MM, Akanbi (2012). "The Case For The Integration". African Journal of Social Sciences 2 (2): 41–66. https://citeseerx.ist.psu.edu/document?repid=rep1&type=pdf&doi=e37133a34951f4d2873ad44347bde24848b6f50c. 
  15. M.M., Akanbi; L.A., Abdulrauf; A.A., Daibu (2015). "Customary arbitration in Nigeria: a review of extant judicial parameters and the need for paradigm shift.". Journal of Sustainable Development Law and Policy 6 (1): 199–201. doi:10.4314/jsdlp.v6i1.9. https://www.ajol.info/index.php/jsdlp/article/view/128024.