Jump to content

Ọ̀rànmíyàn

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Oranyan)
Ere Oranmiyan

Nínú ìtàn àròsọ/àtẹnudẹ́nu ilẹ̀ Yorùbá Ọ̀rànmíyan tàbí Ọ̀rányàn jẹ́ Ọba Láti Ilé-Ifẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ó tún jẹ́ ọmọ Odùduwà. Ohun ni ìtàn àròsọ ẹnu yí sọ wípé ó dá ìlú Ọ̀yọ́ sílẹ̀. [1][2]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. Babarinsa, Dare (2019-04-25). "The restless children of Oranmiyan". The Guardian Nigeria News. Archived from the original on 2019-11-23. Retrieved 2019-11-23. 
  2. oloolutof (2017-02-24). "Oranmiyan Omoluabi Odede the first Alaafin of Oyo". Yoruba Traditional & Cultural Renaissance. Retrieved 2019-11-23.