Àlàdé Arómirẹ́: Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò
Ìlà 5: | Ìlà 5: | ||
==Iṣẹ́ rẹ̀== |
==Iṣẹ́ rẹ̀== |
||
Gẹ́gẹ́ bí òṣèré, ó ti rí gbogbo rògbàdìyàn àti akitiyan tí ó wà nínú lílo ìlànà "atabloid" tí àwọn àgbà òṣèré bíi: [[ Moses |
Gẹ́gẹ́ bí òṣèré, ó ti rí gbogbo rògbàdìyàn àti akitiyan tí ó wà nínú lílo ìlànà "atabloid" tí àwọn àgbà òṣèré bíi: [[ Moses Ọláìyá Adéjùmọ̀]], Olóyè [[Hubert Ògúndé]] ń lò láti gbé eré jáde tí ó sì ń ná wọn lówó gegere kí eré náà ó tó jáde síta fún àwọn ènìyàn. Ó dá ṣíṣe yíya eré sinimá àgbéléwò àkókọ́ sílẹ̀ tí ó pe àkọọ́lé rẹ̀ ní ''Ẹkùn'' ní ọdún 1989.<ref name="Modern Ghana 2007">{{cite web | title=I STARTED NOLLYWOOD...ALADE AROMIRE | website=Modern Ghana | date=2007-10-01 | url=https://www.modernghana.com/movie/1651/i-started-nollywoodalade-aromire.html | access-date=2020-10-29}}</ref> |
||
==Àwọn ìtọ́kasí== |
==Àwọn ìtọ́kasí== |
Àtúnyẹ̀wò lọ́wọ́lọ́wọ́ ní 22:16, 29 Oṣù Kẹ̀wá 2020
Muyideen Agboọlá Àlàdé Arómirẹ́ tí gbogbo ènìyàn tún mọ̀ sí Àlàdé Arómirẹ́ tí wọ́n bí ní Ìpínlẹ̀ Èkó ní ọjọ́ Kẹtàlá oṣù Kẹjọ ọdún 1963 jẹ́ gbajú-gbajà òṣèré ìtàgé, agbéré-jáde, àti ònkọ̀tàn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1]
Ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Àlàdé lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ti Ansar-ud-Deen tí ó wà ní Alakoso ní Ìpínlẹ̀ Èkó, tí ó sì lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ girama ti Ansar-ud-Deen College, ní Ìlú Ìsọlọ̀ ní Ìpínlẹ̀ Èkó kan náà. Ó tún kọ́ ẹ̀kọ́ nípa eré oníṣẹ́ ní School of Arts rí ó wà ní Apapa.
Iṣẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Gẹ́gẹ́ bí òṣèré, ó ti rí gbogbo rògbàdìyàn àti akitiyan tí ó wà nínú lílo ìlànà "atabloid" tí àwọn àgbà òṣèré bíi: Moses Ọláìyá Adéjùmọ̀, Olóyè Hubert Ògúndé ń lò láti gbé eré jáde tí ó sì ń ná wọn lówó gegere kí eré náà ó tó jáde síta fún àwọn ènìyàn. Ó dá ṣíṣe yíya eré sinimá àgbéléwò àkókọ́ sílẹ̀ tí ó pe àkọọ́lé rẹ̀ ní Ẹkùn ní ọdún 1989.[2]
Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "Meet Alade Aromire, The Man Who Changed The Face Of Yoruba Movies And How He Died 11 Years Ago". City People Magazine. 2019-05-15. Retrieved 2020-10-29.
- ↑ "I STARTED NOLLYWOOD...ALADE AROMIRE". Modern Ghana. 2007-10-01. Retrieved 2020-10-29.