Àlàdé Arómirẹ́: Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Content deleted Content added
 
Ìlà 5: Ìlà 5:


==Iṣẹ́ rẹ̀==
==Iṣẹ́ rẹ̀==
Gẹ́gẹ́ bí òṣèré, ó ti rí gbogbo rògbàdìyàn àti akitiyan tí ó wà nínú lílo ìlànà "atabloid" tí àwọn àgbà òṣèré bíi: [[ Moses ỌláìyáAdéjùmọ̀]], Olóyè [[Hubert Ògúndé]] ń lò láti gbé eré jáde tí ó sì ń ná wọn lówó gegere kí eré náà ó tó jáde síta fún àwọn ènìyàn. Ó dá ṣíṣe yíya eré sinimá àgbéléwò àkókọ́ sílẹ̀ tí ó pe àkọọ́lé rẹ̀ ní ''Ẹkùn'' ní ọdún 1989.<ref name="Modern Ghana 2007">{{cite web | title=I STARTED NOLLYWOOD...ALADE AROMIRE | website=Modern Ghana | date=2007-10-01 | url=https://www.modernghana.com/movie/1651/i-started-nollywoodalade-aromire.html | access-date=2020-10-29}}</ref>
Gẹ́gẹ́ bí òṣèré, ó ti rí gbogbo rògbàdìyàn àti akitiyan tí ó wà nínú lílo ìlànà "atabloid" tí àwọn àgbà òṣèré bíi: [[ Moses Ọláìyá Adéjùmọ̀]], Olóyè [[Hubert Ògúndé]] ń lò láti gbé eré jáde tí ó sì ń ná wọn lówó gegere kí eré náà ó tó jáde síta fún àwọn ènìyàn. Ó dá ṣíṣe yíya eré sinimá àgbéléwò àkókọ́ sílẹ̀ tí ó pe àkọọ́lé rẹ̀ ní ''Ẹkùn'' ní ọdún 1989.<ref name="Modern Ghana 2007">{{cite web | title=I STARTED NOLLYWOOD...ALADE AROMIRE | website=Modern Ghana | date=2007-10-01 | url=https://www.modernghana.com/movie/1651/i-started-nollywoodalade-aromire.html | access-date=2020-10-29}}</ref>


==Àwọn ìtọ́kasí==
==Àwọn ìtọ́kasí==

Àtúnyẹ̀wò lọ́wọ́lọ́wọ́ ní 22:16, 29 Oṣù Kẹ̀wá 2020

Muyideen Agboọlá Àlàdé Arómirẹ́ tí gbogbo ènìyàn tún mọ̀ sí Àlàdé Arómirẹ́ tí wọ́n bí ní Ìpínlẹ̀ Èkó ní ọjọ́ Kẹtàlá oṣù Kẹjọ ọdún 1963 jẹ́ gbajú-gbajà òṣèré ìtàgé, agbéré-jáde, àti ònkọ̀tàn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1]

Ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àlàdé lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ti Ansar-ud-Deen tí ó wà ní Alakoso ní Ìpínlẹ̀ Èkó, tí ó sì lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ girama ti Ansar-ud-Deen College, ní Ìlú Ìsọlọ̀ ní Ìpínlẹ̀ Èkó kan náà. Ó tún kọ́ ẹ̀kọ́ nípa eré oníṣẹ́ ní School of Arts rí ó wà ní Apapa.

Iṣẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Gẹ́gẹ́ bí òṣèré, ó ti rí gbogbo rògbàdìyàn àti akitiyan tí ó wà nínú lílo ìlànà "atabloid" tí àwọn àgbà òṣèré bíi: Moses Ọláìyá Adéjùmọ̀, Olóyè Hubert Ògúndé ń lò láti gbé eré jáde tí ó sì ń ná wọn lówó gegere kí eré náà ó tó jáde síta fún àwọn ènìyàn. Ó dá ṣíṣe yíya eré sinimá àgbéléwò àkókọ́ sílẹ̀ tí ó pe àkọọ́lé rẹ̀ ní Ẹkùn ní ọdún 1989.[2]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Meet Alade Aromire, The Man Who Changed The Face Of Yoruba Movies And How He Died 11 Years Ago". City People Magazine. 2019-05-15. Retrieved 2020-10-29. 
  2. "I STARTED NOLLYWOOD...ALADE AROMIRE". Modern Ghana. 2007-10-01. Retrieved 2020-10-29.