Rótìmí Akérédolú

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Àdàkọ:EngvarB

His Excellency

Olúwarótìmí Ọdúnayọ̀ Akérédolú

Governor of Ondo State
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
24 February 2017
AsíwájúOlusegun Mimiko
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí
Oluwarotimi Odunayo Akeredolu

21 Oṣù Keje 1956 (1956-07-21) (ọmọ ọdún 67)
Owo, Ondo State
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress
(Àwọn) olólùfẹ́Betty Anyanwu-Akeredolu
Alma materObafemi Awolowo University
OccupationPolitician
Lawyer
Websiteaketi.org

Olúwarótìmí Ọdúnayọ̀ Akérédolú, SAN, or Rótìmí Akérédolú, ní wọ́n bí ní Ọjọ́ kọkànlélógún oṣù keje ọdún 1956 (21st July 1956) jẹ́ òṣèlú, agbẹjọ́rọ̀ àti Gómìnà ìpínlẹ̀ Oǹdó lọ́wọ́lọ́wọ́ ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà , [1] Ó jẹ́ amòfin-àgbà SAN tí ó ti joyè alága àwọn amọ̀fin Nigerian Bar Association lọ́dún 2008.[2] Kí ó tó di Gómìnà ìpínlẹ̀ Oǹdó, ó jẹ́ ọ̀kan lára olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ amọ̀fin, Olujinmi & Akeredolu,[3] a Law Firm he co-founded with Chief Akin Olujinmi, a former Attorney General and Minister for Justice in Nigeria. Ó gbapò ìṣèjọba ìpínlẹ̀ Oǹdó lọ́wọ́ Gómìnà-àná ti ìpínlẹ̀ náà, Olúṣẹ́gun Mimiko

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Breaking Ondo decides Inec officially declares Rotimi Akeredolu Governor elect". www.premiumtimesng.com. Retrieved 27 November 2016. 
  2. "Nigerian Bar". www.nigerianbar.org. Archived from the original on 8 October 2011. Retrieved 27 November 2016. 
  3. "Olujinmi Akeredolu". Retrieved 27 November 2016.