Richard Bamisile

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Richard bamisile)
Richard Bamisile
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí
Richard Olufemi Bamisile

27 Oṣù Kẹ̀sán 1965 (1965-09-27) (ọmọ ọdún 58)
Ibadan, Western State, Nigeria (now in Oyo State, Nigeria)
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress (APC)
Alma materGovernment College, Lagos
University of Ado-Ekiti (now Ekiti State University)
OccupationPolitician, businessman
Websiteteambafem.com
Nickname(s)BAFEM

Richard Olufemi Bamisile (ẹni tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí BAFEM; wọ́n bí i ní 27 September 1965) jẹ́ Olóṣèlú Nàìjíríà tí ó sì jẹ́ ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin tó ń ṣojú Agbègbè Gúúsù Èkìtì II.[1] Ó tún jẹ́ Agbẹnusọ ilé aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkìtì nígbà kan rí (ìjókòó kẹta).[2] Ó wà lára àwọn olùdíje fún ipò Gómìnà nínú ètò ìdìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú (APC) ní 2019.[3][4][5]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Ekiti 2022: House of Reps member, Bamisile, joins guber race". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-06-10. Retrieved 2022-03-18. 
  2. "Ekiti 2022: House of Reps member, Bamisile, joins guber race". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-06-10. Retrieved 2022-02-21. 
  3. "ekiti-2018 nobody can rig apc primary". Daily POst. March 30, 2018. 
  4. "Appeal court nullifies election in ekiti". osundefender.com. Archived from the original on 2018-08-29. Retrieved 2023-12-07. 
  5. "ekiti guber elections olufemi bamisile becomes picks up apc nomination form". niajaparrot.com. Archived from the original on 2018-06-20. Retrieved 2023-12-07.