Samuel Olatunde Fadahunsi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Samuel Olatunde Fadahunsi
President of the Council for the Regulation of Engineering in Nigeria (COREN)
In office
1977–1986
President of the Nigerian Society of Engineers (NSE)
In office
1967–1970
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí(1920-03-17)17 Oṣù Kẹta 1920
Nigeria
Aláìsí12 August 2014(2014-08-12) (ọmọ ọdún 94)
Lagos, Lagos State, Nigeria

Samuel Olatunde Fadahunsi (17 March 1920 – 12 August 2014) fìgbà kan jẹ́ onímọ̀-ẹ̀rọ àti ààrẹ ẹgbẹ́ COREN, tó jẹ́ àjọ tó ń rí sí ìmọ̀-ẹ̀rọ ní Nàìjíríà.[1]

Ayé àti iṣẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kẹta ọdún 1920 ni wọ́n bí Samuel sí Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, tó wà ní apá Ìwọ̀-oòrùn iẹ̀ Nàìjíríà. Ilé-ìwé Saint John ní, Iloro, Ilesha, Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ni ó lọ, láti ọdún 1927 wọ 1936. Ó tún lọ Government College, Ibadan, láti ọdún 1937 wọ ọdún 1942. Ní ọdún 1948, ó gba ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tó fi gba oyè bachelor's degree nínú ìmọ̀-ẹ̀rọ Civil engineering ní Battersea Polytechnic ní ìlú London.[2] Lẹ́yìn tó gba oyè ẹ̀kọ́ yìí ní ọdún 1952, ó darapọl mọ́ Cubits, tó jẹ́ ilé-iṣẹ́ ẹ̀rọ ní ilè Britain, ó sì ṣiṣé níbẹ̀ fún ọdún méjì.[3] Ó padà sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà níbi tí ó ti di onímọ̀-ẹ̀rọ ní kíkún.[4] Ó kúrọ̀ ní England ní ọdún 1957 fún ẹ̀kọ́ oyè PGD, gẹ́gé bí onímọ̀-ẹ̀rọ tó ń rí ọ̀rọl omi. Ó parí ẹ̀kọ́ náà ní ọdún 1958, ó sì padà sí Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí i àgbà onímọ̀ ẹ̀rọ ní àwọn ìlú tó wà ní apá Ìwọ̀-oòrùn bí i Abẹ́òkúta, Ìbàdàn àti Benin.[5] Ó padà di Chief Water Engineer ní old Western Region of Nigeria (1960-1963). Bákàn náà ni ó di Deputy Chief Executive Officer láti ọdún 1963 wọ ọdún 1965 àti Chief Executive Officer, Lagos Executive Development Board (LEDB), now Lagos State Development and Property Corporation (LSDPC) (1965-1972).[6][7][8] Ó tún ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i Chairman of Industrial Research Council of Nigeria láàárín ọdún 1971 àti 1974[9]

Ẹgbẹ́ tó dara pọ̀ mọ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Foundation Fellow of The Nigerian Academy of Engineering.[10]

Àmì-ẹ̀yẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Certificate of Honour, Nigerian Boys Scouts Movement.
  • Officer of the Order of Niger, OFR (1982)
  • Commander of the Order of Niger, CON (2002)[11]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Chukwuma Okparaocha-Lagos. "Obasanjo, others pay tribute to late housing guru, Fadahunsi". Archived from the original on 2015-04-13.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. Dapo Fafowora. "Chief Samuel Olatunde Fadahunsi, CON (1920- 2014)". The Nation. 
  3. "Chief S.O. Fadahunsi, OFR, CON: Tribute to an exceptional leader and engineer - Vanguard News". Vanguard News. 
  4. "BiafraNigeriaWorld: The Authority on BiafraNigeria". 
  5. "Institute Concludes Research On Bad Roads". Archived from the original on 2015-04-11.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  6. "Nigeria HomePage - Breaking News, Business, Sports, Entertainment and Video News". Archived from the original on 2015-04-12.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  7. Reflections on the events of my life. OCLC 839303897. https://www.worldcat.org/oclc/839303897. 
  8. Fadahunsi, Samuel Olatunde (2010). Reflections on the Events of My Life. ISBN 9789780694166. https://books.google.com/books?id=JQ0KmwEACAAJ. 
  9. Our Correspondent. "New Telegraph – Institute concludes research on bad roads". Archived from the original on 2015-04-13.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  10. RapidxHTML. "The Nigeria Academy of Engineering :: promoting excellence in technology and engineering training and practice to ensure the technological growth and economic development of Nigeria". Archived from the original on 2016-12-16. Retrieved 2024-02-08. 
  11. "Chief Samuel Olatunde Fadahunsi, CON (1920- 2014) - The Nation Newspaper".