Sesi Oluwaseun Whingan

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Sesi Oluwaseun Whingan

Sesi Oluwaseun Whingan jẹ́ òṣèlú ọmọ orílẹ̀-èdè Nigerian. Ó jẹ́ ọmọ ilẹ̀-ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin lọ́wọ́lọ́wọ́, tí ó ń ṣojú fún ẹkùn-ìdìbò tí Badagry nílé ìgbìmọ̀-aṣòfin ẹlẹ́kẹwàá tí Nigeria láti oṣù kẹfà ọdún 2023. [1][2][3][4][5] Ó ti dábàá àbádòfin mẹ́ẹ̀ẹ́dógún nílé igbimọ̀-aṣòfin.[6]

Iṣẹ́ òṣèlú[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Sesi Oluwaseun Whingan jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́-òṣèlú All Progressive Congress (APC). Lọ́dún 2023, ó dárapọ̀ mọ́ òṣèlú, ó díje ó sì wọlé gẹ́gẹ́ bí ọmọ-ẹgbẹ́ aṣojú-ṣòfin láti ṣojú ẹkùn-ìdìbò Badagry Federal Constituency pẹ̀lú ìbò tí iye rẹ̀ jẹ́ 34,970 votes.[7][8][9] Òun ni igbá-kejì alága fún ìgbìmọ̀ lórí ọ̀rọ̀ wíwàkùsà epo-rọ̀bì (Deputy Chairman of the House Committee on Petroleum Resources (upstream)) nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin kẹwàá lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà [10]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Sesi Whingan: A remarkable performance by Lagos' youngest Reps member". The Nation Newspaper. 2023-10-03. Retrieved 2024-04-06. 
  2. "Lagos: Badagry indigenes urged to preserve culture". Peoples Gazette Nigeria. 2024-01-05. Retrieved 2024-04-06. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  3. "Lawmaker assures speedy completion of Lagos-Badagry Expressway". Peoples Gazette Nigeria. 2023-10-15. Retrieved 2024-04-06. 
  4. Nigeria, Guardian (2024-04-04). "FG pledges to support, nurture tourism in Badagry". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Retrieved 2024-04-06. 
  5. Onyegbula, Esther (2024-04-04). "FG committed to nurturing tourism growth in Badagry – Ade-John". Vanguard News. Retrieved 2024-04-06. 
  6. "Nigerians should be patient with Tinubu, NASS making laws to improve lives: Rep". Peoples Gazette Nigeria. 2023-12-29. Retrieved 2024-04-06. 
  7. Falade, Tomi (2021-03-20). "2023: Young philanthropist, Sesi Whingan declares interest to vie for House of Reps in Badagry". Independent Newspaper Nigeria. Retrieved 2024-04-21. 
  8. Premium Times Nigeria https://www.premiumtimesng.com/regional/ssouth-west/584719-nigeriadecides2023-apc-wins-badagry-house-of-reps-seat.html?tztc=1. Retrieved 2024-04-21.  Missing or empty |title= (help)
  9. "Sesi Whigan wins APC Badagry Rep seat". Sunrise News. 2022-06-01. Retrieved 2024-04-21. 
  10. "Reps seek continuous review of PIA to address global, local needs". Vanguard News. 2023-12-12. Retrieved 2024-04-21.