Àtòjọ Àwọn Orílẹ̀-èdè Áfíríkà Nípa Bi Wọ́n Ṣe Pọ̀ Tó Níye
Ìrísí
Èyí ni Àtòjọ Àwọn Orílẹ̀-èdè Àfíríkà Nípa Bí Wọ́n Ṣe Pọ̀ Tó Níye, a kọ èyí sílẹ̀ nípa lílo ìwòye iye ènìyàn tí ó wà lórílẹ̀ èdè kọ̀ọ̀kan pẹ̀lú Ìtọ́kasí ètò ìkànìyàn tí wọ́n ṣe lẹ́yìn lórílẹ̀ èdè kọ̀ọ̀kan. Láìsí àní-àní, ilẹ̀ Áfíríkà ṣì ní ilẹ̀ tí ó ń dàgbà jùlọ níye ènìyàn ní gbogbo àgbáyé lẹ́yìn ilẹ̀ Asia. [1] Ìdá ọgọ́ta (60%) àwọn ènìyàn Áfíríkà ní wọ́n wà ní ọmọ ọjọ́ orí mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n tàbí kéré sí iye ọjọ́ orí yẹn sí ọjọ́ orí wọn,[2] èyí wá mú kí ṣíṣe àtẹ ìdàgbàsókè iye ènìyàn tí ó wà lórílẹ̀ èdè kọ̀ọ̀kan dá lé bí ètò ìṣèjọba àti ìdàgbàsókè ètò ọ̀rọ̀-ajé ṣe ṣe pàtàkì tó.
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2021-03-08. Retrieved 2020-02-05.
- ↑ https://www.un.org/esa/socdev/documents/youth/fact-sheets/YouthPOP.pdf
- ↑ "African countries by population (2019)". Retrieved 15 September 2019. Unknown parameter
|url-status=ignored (help) - ↑ Administration is split between Morocco and the Sahrawi Arab Democratic Republic, both of which claim the entire territory.
Àwọn ẹ̀ka:
- Pages with citations using unsupported parameters
- Webarchive template wayback links
- All articles with dead external links
- Articles with dead external links from December 2017
- Articles with invalid date parameter in template
- Articles with permanently dead external links
- Articles with dead external links from August 2018